1 Kronika 1 – YCB & NVI-PT

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

1 Kronika 1:1-54

Ìran Adamu títí de Abrahamu

Títí dé ọmọkùnrin Noa

11.1-53: Gẹ 5; 10; 11; 25; 36.Adamu, Seti, Enoṣi,

2Kenani, Mahalaleli, Jaredi,

3Enoku, Metusela, Lameki,

Noa.

4Àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti.

Àwọn Ọmọ Jafeti

5Àwọn ọmọ Jafeti ni:

Gomeri, Magogu, Madai; Jafani, Tubali, Meṣeki àti Tirasi.

6Àwọn ọmọ Gomeri ni:

Aṣkenasi, Rifàti àti Togarma.

7Àwọn ọmọ Jafani ni:

Eliṣa, Tarṣiṣi, Kittimu, àti Dodanimu.

Àwọn ọmọ Hamu

8Àwọn ọmọ Hamu ni:

Kuṣi, Misraimu, Puti, àti Kenaani.

9Àwọn ọmọ Kuṣi ni:

Seba, Hafila, Sabta, Raama, àti Ṣabteka.

Àwọn ọmọ Raama:

Ṣeba àti Dedani.

10Kuṣi sì bí Nimrodu:

Ẹni tí ó di alágbára jagunjagun ní ayé.

11Misraimu sì bí

Ludimu, Anamimu, Lehabimu, Naftuhimu, 12Patrusimu, Kasluhimu, (láti ọ̀dọ̀ ẹni tí àwọn ará Filistini ti wá) àti àwọn ará Kaftorimu.

13Kenaani sì bí Sidoni àkọ́bí rẹ̀,

àti Heti, 14Àti àwọn ará Jebusi, àti àwọn ará Amori, àti àwọn ará Girgaṣi, 15àti àwọn ará Hifi, àti àwọn ará Arki, àti àwọn ará Sini, 16àti àwọn ará Arfadi, àti àwọn ará Ṣemari, àti àwọn ará Hamati.

Àwọn ará Ṣemu.

17Àwọn ọmọ Ṣemu ni:

Elamu, Aṣuri, Arfakṣadi, Ludi àti Aramu.

Àwọn ọmọ Aramu:

Usi, Huli, Geteri, àti Meṣeki.

18Arfakṣadi sì bí Ṣela,

Ṣela sì bí Eberi.

19Eberi sì bí ọmọ méjì:

ọ̀kan ń jẹ́ Pelegi, nítorí ní ìgbà ọjọ́ rẹ̀ ni ilẹ̀ ya; orúkọ arákùnrin rẹ̀ ni Joktani.

20Joktani sì bí

Almodadi, Ṣelefi, Hasarmafeti, Jera. 21Hadoramu, Usali, Dikla, 22Ebali, Abimaeli, Ṣeba. 23Ofiri, Hafila, àti Jobabu. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Joktani.

24Ṣemu, Arfakṣadi, Ṣela,

25Eberi, Pelegi. Reu,

26Serugu, Nahori, Tẹra:

27Àti Abramu (tí ń ṣe Abrahamu).

Ìdílé Abrahamu

28Àwọn ọmọ Abrahamu: Isaaki àti Iṣmaeli.

Àwọn ọmọ Hagari

29Èyí ni àwọn ọmọ náà:

Nebaioti àkọ́bí Iṣmaeli: Kedari, Adbeeli, Mibsamu, 30Miṣima, Duma, Massa, Hadadi, Tema, 31Jeturi, Nafiṣi, àti Kedema.

Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Iṣmaeli.

Àwọn ọmọ Ketura

32Àwọn ọmọ Ketura, obìnrin Abrahamu:

Simrani, Jokṣani Medani, Midiani Iṣbaki àti Ṣua.

Àwọn ọmọ Jokṣani:

Ṣeba àti Dedani.

33Àwọn ọmọ Midiani:

Efani, Eferi, Hanoku, Abida àti Eldaa.

Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ìran Ketura.

Àwọn Ìran Sara

34Abrahamu sì jẹ́ baba Isaaki:

Àwọn ọmọ Isaaki:

Esau àti Israẹli.

Àwọn ọmọ Esau

35Àwọn ọmọ Esau:

Elifasi, Reueli, Jeuṣi, Jalamu, àti Kora.

36Àwọn ọmọ Elifasi:

Temani, Omari, Sefi, Gatamu àti Kenasi;

láti Timna: Amaleki.

37Àwọn ọmọ Reueli:

Nahati, Sera, Ṣamma àti Missa.

Àwọn ènìyàn Seiri ní Edomu

38Àwọn ọmọ Seiri:

Lotani, Ṣobali, Sibeoni, Ana, Diṣoni, Eseri àti Diṣani.

39Àwọn ọmọ Lotani:

Hori àti Homamu: Timna sì ni arábìnrin Lotani.

40Àwọn ọmọ Ṣobali:

Afiani, Manahati, Ebali, Ṣefo àti Onamu.

Àwọn ọmọ Sibeoni:

Aiah àti Ana.

41Àwọn ọmọ Ana:

Diṣoni.

Àwọn ọmọ Diṣoni:

Hemdani, Eṣbani, Itrani, àti Kerani.

42Àwọn ọmọ Eseri:

Bilhani, Saafani àti Akani.

Àwọn ọmọ Diṣani:

Usi àti Arani.

Àwọn alákòóso Edomu

43Àwọn wọ̀nyí ni ọba tí ó jẹ ní Edomu, kí ó tó di pé ọba kankan jẹ lórí Israẹli:

Bela ọmọ Beori, orúkọ ìlú rẹ̀ ni Dinhaba.

44Nígbà tí Bela kú, Jobabu ọmọ Sera ti Bosra sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.

45Nígbà tí Jobabu kú, Huṣamu láti ilẹ̀ Temani sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.

46Nígbà tí Huṣamu kú, Hadadi ọmọ Bedadi tí ó kọlu Midiani ní ìgbẹ́ Moabu, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Afiti.

47Nígbà tí Hadadi sì kú, Samla láti Masreka, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.

48Samla sì kú, Saulu ti Rehoboti létí odò sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀

49Nígbà tí Saulu kú, Baali-Hanani, ọmọ Akbori jẹ ọba ní ipò rẹ̀.

50Nígbà tí Baali-Hanani kú, Hadadi ni ó jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Pau; orúkọ ìyàwó sì ni Mehetabeeli ọmọbìnrin Matiredi, ọmọbìnrin Mesahabu. 51Hadadi sì kú pẹ̀lú.

Àwọn baálẹ̀ Edomu ni:

baálẹ̀ Timna, baálẹ̀ Alfa, baálẹ̀ Jeteti 52baálẹ̀ Oholibama, baálẹ̀ Ela, baálẹ̀ Pinoni. 53baálẹ̀ Kenasi, baálẹ̀ Temani, baálẹ̀ Mibsari, 54Magdieli àti Iramu.

Àwọn wọ̀nyí ni baálẹ̀ Edomu.

Nova Versão Internacional

1 Crônicas 1:1-54

A Descendência de Adão

1Adão, Sete, Enos,

2Cainã, Maalaleel, Jarede,

3Enoque, Matusalém, Lameque,

Noé.

4Estes foram os filhos de Noé1.4 Conforme a Septuaginta. O Texto Massorético não traz os filhos de Noé.: Sem, Cam e Jafé.

Os Descendentes dos Filhos de Noé

5Estes foram os filhos1.5 Filhos pode significar descendentes ou sucessores ou nações; também nos versículos 6.9,17 e 23. de Jafé:

Gômer, Magogue, Madai, Javã, Tubal, Meseque e Tirás.

6Estes foram os filhos de Gômer:

Asquenaz, Rifate1.6 Muitos manuscritos dizem Difate. e Togarma.

7Estes foram os filhos de Javã:

Elisá, Társis, Quitim e Rodanim1.7 Muitos manuscritos dizem Dodanim..

8Estes foram os filhos de Cam:

Cuxe, Mizraim1.8 Isto é, Egito; também no versículo 11., Fute e Canaã.

9Estes foram os filhos de Cuxe:

Sebá, Havilá, Sabtá, Raamá e Sabtecá.

Estes foram os filhos de Raamá:

Sabá e Dedã.

10Cuxe gerou1.10 Gerar pode ter o sentido de ser ancestral ou ser predecessor; também nos versículos 11, 13, 18 e 20.

Ninrode, o primeiro homem poderoso na terra.

11Mizraim gerou

os luditas, os anamitas, os leabitas, os naftuítas, 12os patrusitas, os casluítas, dos quais se originaram os filisteus, e os caftoritas.

13Canaã gerou

Sidom, seu filho mais velho1.13 Ou os sidônios, os primeiros, e Hete1.13 Ou e os hititas, 14como também os jebuseus, os amorreus, os girgaseus, 15os heveus, os arqueus, os sineus, 16os arvadeus, os zemareus e os hamateus.

17Estes foram os filhos de Sem:

Elão, Assur, Arfaxade, Lude e Arã.

Estes foram os filhos de Arã:1.17 Muitos manuscritos não trazem essa linha. Veja Gn 10.23.

Uz, Hul, Géter e Meseque.

18Arfaxade gerou Salá,

e este gerou Héber.

19A Héber nasceram dois filhos:

um deles se chamou Pelegue1.19 Pelegue significa divisão., porque em sua época a terra foi dividida; seu irmão chamou-se Joctã.

20Joctã gerou

Almodá, Salefe, Hazarmavé, Jerá, 2 21Adorão, Uzal, Dicla, 22Obal1.22 Muitos manuscritos dizem Ebal., Abimael, Sabá, 23Ofir, Havilá e Jobabe. Todos esses foram filhos de Joctã.

A Descendência de Sem

24Sem, Arfaxade1.24 Conforme o Texto Massorético. Alguns manuscritos da Septuaginta dizem Arfaxade, Cainã. Veja Gn 11.12,13., Salá,

25Héber, Pelegue, Reú,

26Serugue, Naor, Terá

27e Abrão, que é Abraão.

Os Descendentes de Abraão

28Estes foram os filhos de Abraão: Isaque e Ismael.

29Foram estes os seus descendentes:

Nebaiote, o filho mais velho de Ismael, Quedar, Adbeel, Mibsão, 30Misma, Dumá, Massá, Hadade, Temá, 31Jetur, Nafis e Quedemá.

Esses foram os filhos de Ismael.

32Estes foram os filhos de Abraão com sua concubina Quetura:

Zinrã, Jocsã, Medã, Midiã, Isbaque e Suá.

Foram estes os filhos de Jocsã:

Sabá e Dedã.

33Foram estes os filhos de Midiã:

Efá, Éfer, Enoque, Abida e Elda.

Todos esses foram descendentes de Quetura.

34Abraão gerou Isaque.

Estes foram os filhos de Isaque:

Esaú e Israel.

Os Descendentes de Esaú

35Estes foram os filhos de Esaú:

Elifaz, Reuel, Jeús, Jalão e Corá.

36Estes foram os filhos de Elifaz:

Temã, Omar, Zefô1.36 Muitos manuscritos dizem Zefi. Veja Gn 36.11., Gaetã e Quenaz;

e Amaleque, de Timna, sua concubina1.36 Muitos manuscritos dizem Gaetã, Quenaz, Timna e Amaleque. Veja Gn 36.12..

37Estes foram os filhos de Reuel:

Naate, Zerá, Samá e Mizá.

Os Descendentes de Seir

38Estes foram os filhos de Seir:

Lotã, Sobal, Zibeão, Aná, Disom, Ézer e Disã.

39Estes foram os filhos de Lotã:

Hori e Homã. Lotã tinha uma irmã chamada Timna.

40Estes foram os filhos de Sobal:

Alvã1.40 Muitos manuscritos dizem Aliã. Veja Gn 36.23., Manaate, Ebal, Sefô e Onã.

Estes foram os filhos de Zibeão:

Aiá e Aná.

41Este foi o filho de Aná:

Disom.

Estes foram os filhos de Disom:

Hendã1.41 Muitos manuscritos dizem Hanrão. Veja Gn 36.26., Esbã, Itrã e Querã.

42Estes foram os filhos de Ézer:

Bilã, Zaavã e Acã1.42 Muitos manuscritos dizem Jaacã. Veja Gn 36.27..

Estes foram os filhos de Disã1.42 Hebraico: Disom, variante de Disã.:

Uz e Arã.

Os Reis e os Chefes de Edom

43Estes foram os reis que reinaram no território de Edom antes que os israelitas tivessem um rei:

Belá, filho de Beor. Sua cidade chamava-se Dinabá.

44Belá morreu; e Jobabe, filho de Zerá, de Bozra, foi o seu sucessor.

45Jobabe morreu; e Husã, da terra dos temanitas, foi o seu sucessor.

46Husã morreu; e Hadade, filho de Bedade, que tinha derrotado os midianitas na terra de Moabe, foi o seu sucessor. Sua cidade chamava-se Avite.

47Hadade morreu; e Samlá de Masreca foi o seu sucessor.

48Samlá morreu; e Saul, de Reobote, próxima ao Eufrates1.48 Hebraico: ao Rio., foi o seu sucessor.

49Saul morreu; e Baal-Hanã, filho de Acbor, foi o seu sucessor.

50Baal-Hanã morreu, e Hadade foi o seu sucessor. Sua cidade chamava-se Paú1.50 Muitos manuscritos dizem Paí. Veja Gn 36.39., e o nome de sua mulher era Meetabel, filha de Matrede e neta de Mezaabe.

51Após a morte de Hadade, Edom foi governada pelos seguintes chefes:

Timna, Alva, Jetete, 52Oolibama, Elá, Pinom, 53Quenaz, Temã, Mibzar, 54Magdiel e Irã.

Foram esses os chefes de Edom.