Salmos 87 – OL & YCB

O Livro

Salmos 87:1-7

Salmo 87

Salmo e Cântico dos descendentes de Coré.

1Sião tem os seus fundamentos

entre as montanhas santas de Deus.

2O Senhor ama os portões de Sião,

mais do que qualquer outra morada de Jacob.

3Coisas maravilhosas se dizem de ti, ó cidade de Deus! (Pausa)

4“Gente de Raab87.4 Este nome hebraico transmite a ideia de um monstro marinho que representava o caos e, por vezes, o Egito. e da Babilónia

estará entre os que me reconhecem como seu Deus;

gentes da Filisteia, de Tiro e de Cuche

serão consideradas cidadãos de Jerusalém.”

5E de Sião se dirá:

“Este e aquele nasceram ali!

Foi o Altíssimo que a estabeleceu.”

6E o Senhor os inscreverá no registo dos povos

como tendo nascido ali. (Pausa)

7E os cantores, acompanhados de instrumentistas,

a louvarão dizendo:

“Tu és a fonte de todo o bem da minha vida!”

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 87:1-7

Saamu 87

Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Orin.

1Ó ti fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ sórí òkè mímọ́;

2Olúwa fẹ́ràn ẹnu-ọ̀nà Sioni

ju gbogbo ibùgbé Jakọbu lọ.

3Ohun ológo ni a sọ nípa rẹ̀,

ìlú Ọlọ́run;

4“Èmi ó dárúkọ Rahabu àti Babeli

láàrín àwọn tí ó jẹ́wọ́ mi:

Filistia pẹ̀lú, àti Tire, pẹ̀lú Kuṣi

yóò sọ pé, ‘Èyí ni a bí ní Sioni.’ ”

5Nítòótọ́, ti Sioni ni a ó sọ,

“Eléyìí àti eléyìí ni a bí nínú rẹ̀,

àti Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo ni yóò fìdí rẹ̀ múlẹ̀.”

6Olúwa yóò kọ nínú àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀:

“Eléyìí ni a bí ní Sioni.”

7Àti àwọn olórin àti àwọn tí ń lu

ohun èlò orin yóò wí pé,

“Gbogbo orísun mi ń bẹ nínú rẹ.”