Salmos 122 – OL & YCB

O Livro

Salmos 122:1-9

Salmo 122

Cântico de peregrinação. Salmo de David.

1Fiquei cheio de alegria quando me disseram:

“Vamos subir a Jerusalém, à casa do Senhor!”

2E agora aqui estamos, Jerusalém,

pisando o teu chão, dentro das tuas portas!

3Aqui estamos nesta grande cidade,

tão cheia de gente!

4Todas as tribos de Israel, as tribos do Senhor,

sobem até aqui, conforme o mandamento de Deus,

para dar ao Senhor louvor pelo seu nome!

5É aqui que se encontram os tronos de julgamento,

os tronos da casa de David.

6Orem pela paz de Jerusalém!

Todos os que te amam hão de prosperar na vida.

7Que haja paz no teu interior

e felicidade nas tuas fortalezas!

8É pensando no bem dos meus irmãos e amigos

que repito: “Haja paz no teu meio!”

9É também por causa do templo do Senhor, nosso Deus,

que desejo profundamente o teu bem!

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 122:1-9

Saamu 122

Orin fún ìgòkè. Ti Dafidi.

1Inú mi dùn nígbà tí wọ́n wí fún mi pé

Ẹ jẹ́ kí á lọ sílé Olúwa.

2Ẹsẹ̀ wa yóò dúró ní ẹnu ibodè rẹ,

ìwọ Jerusalẹmu.

3Jerusalẹmu, ìwọ tí a kọ́ bí ìlú

tí o fi ara mọ́ra pọ̀ ṣọ̀kan

4Níbi tí àwọn ẹ̀yà máa ń gòkè lọ,

àwọn ẹ̀yà Olúwa,

ẹ̀rí fún Israẹli, láti

máa dúpẹ́ fún orúkọ Olúwa.

5Nítorí ibẹ̀ ni a gbé ìtẹ́ ìdájọ́ kalẹ̀,

àwọn ìtẹ́ ilé Dafidi.

6Gbàdúrà fún àlàáfíà Jerusalẹmu;

àwọn tí ó fẹ́ ọ yóò ṣe rere.

7Kí àlàáfíà kí ó wà nínú odi rẹ̀,

àti ìre nínú ààfin rẹ̀.

8Nítorí àwọn ọkùnrin àti àwọn ẹgbẹ́ mi

èmi yóò wí nísinsin yìí pé,

kí àlàáfíà kí ó wà nínú rẹ̀;

9Nítorí ilé Olúwa Ọlọ́run wa,

èmi yóò máa wá ìre rẹ̀.