Psalm 1 – NIRV & YCB

New International Reader’s Version

Psalm 1:1-6

Book I

Psalms 1–41

Psalm 1

1Blessed is the person who obeys the law of the Lord.

They don’t follow the advice of evil people.

They don’t make a habit of doing what sinners do.

They don’t join those who make fun of the Lord and his law.

2Instead, the law of the Lord gives them joy.

They think about his law day and night.

3That kind of person is like a tree that is planted near a stream of water.

It always bears its fruit at the right time.

Its leaves don’t dry up.

Everything godly people do turns out well.

4Sinful people are not like that at all.

They are like straw

that the wind blows away.

5When the Lord judges them, their life will come to an end.

Sinners won’t have any place among those who are godly.

6The Lord watches over the lives of godly people.

But the lives of sinful people will lead to their death.

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 1:1-6

ÌWÉ KÌN-ÍN-NÍ

Saamu 1–41

Saamu 1

11.1-3: Jr 17.7-8.Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà,

tí kò rìn ní ìmọ̀ àwọn ènìyàn búburú,

ti kò dúró ní ọ̀nà àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀,

tàbí tí kò sì jókòó ní ibùjókòó àwọn ẹlẹ́gàn.

2Ṣùgbọ́n ayọ̀ inú rẹ̀ wà nínú òfin Olúwa

àti nínú òfin rẹ̀ ni ó ń ṣe àṣàrò ní ọ̀sán àti òru.

3Ó dàbí igi tí a gbìn sí etí odò tí ń sàn,

tí ń so èso rẹ̀ jáde ní àkókò rẹ̀

tí ewé rẹ̀ kì yóò rẹ̀.

Ohunkóhun tí ó dáwọ́lé, ni yóò máa yọrí sí rere.

4Kò le rí bẹ́ẹ̀ fún àwọn ènìyàn búburú!

Wọn yóò dàbí ìyàngbò ọkà

tí afẹ́fẹ́ ń fẹ́ dànù.

5Nítorí náà àwọn ènìyàn búburú kì yóò le è dìde dúró ní ìdájọ́,

bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ kì yóò le è dúró ní àwùjọ àwọn olódodo.

6Nítorí Olúwa ń ṣọ́ ọ̀nà àwọn olódodo,

ṣùgbọ́n ọ̀nà àwọn ènìyàn búburú ni yóò ṣègbé.