Zaburi 26 – NEN & YCB

Kiswahili Contemporary Version (Neno: Bibilia Takatifu)

Zaburi 26:1-12

Zaburi 26

Maombi Ya Mtu Mwema

Zaburi ya Daudi.

126:1 1Sam 24:15; Isa 12:2; 25:9; Mit 20:7; Yer 17:7; Za 15:2; 22:4; 40:4; 2Fal 20:3; Dan 3:28; Ebr 10:23Ee Bwana, nithibitishe katika haki,

maana nimeishi maisha yasiyo na lawama;

nimemtumainia Bwana

bila kusitasita.

226:2 Za 7:9; 66:10; Kum 6:6; Eze 11:5; Yer 22:20; 20:12Ee Bwana, unijaribu, unipime,

uuchunguze moyo wangu

na mawazo yangu;

326:3 1Fal 2:4; Za 6:4; 40:11; 43:3; 86:11; 119:30kwa maana upendo wako

uko mbele yangu daima,

nami natembea siku zote

katika kweli yako.

426:4 Za 1:1; 28:3; Mt 6:226:4 Amo 9:6; Zek 10:1Siketi pamoja na watu wadanganyifu,

wala siandamani na wanafiki,

526:5 Za 139:21ninachukia kusanyiko la watenda mabaya

na ninakataa kuketi pamoja na waovu.

626:6 Za 73:13; Mt 27:24Ninanawa mikono yangu kwa kuwa sina hatia,

naikaribia madhabahu yako, Ee Bwana,

726:7 Isa 42:12; 60:6; Yos 3:5; Za 9:1nikitangaza sifa yako kwa sauti kubwa,

huku nikisimulia matendo yako ya ajabu.

826:8 Za 96:6; 122:6; Isa 66:10; 2Nya 7:1; Kut 29:43Ee Bwana, naipenda nyumba yako mahali unakoishi,

mahali ambapo utukufu wako hukaa.

926:9 Za 5:6; 28:3; 55:23; 139:19; Mit 29:10Usiiondoe nafsi yangu pamoja na watenda dhambi,

wala uhai wangu pamoja na wamwagao damu,

1026:10 Za 21:11; Isa 1:23; Ay 36:18; Eze 22:12ambao mikononi mwao kuna mipango miovu,

ambao mikono yao ya kuume imejaa rushwa.

1126:11 Za 31:5; 69:18; 119:134; Tit 2:14Bali mimi ninaishi maisha yasiyo na lawama;

nikomboe na unihurumie.

1226:12 Za 22:25; 27:11; Ay 36:18; Lk 6:17; Isa 26:7; 40:3-4; 45:13; Zek 4:7Miguu yangu imesimama katika uwanja tambarare;

katika kusanyiko kuu nitamsifu Bwana.

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 26:1-12

Saamu 26

Ti Dafidi.

1Ṣe ìdájọ́ mi, Olúwa,

nítorí tí mo ti ń rìn nínú ìwà òtítọ́ ọ̀ mi,

mo sì ti ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú Olúwa

Ǹjẹ́ ẹsẹ̀ mi kì yóò yẹ̀.

2Wádìí mi wò, Ìwọ Olúwa, kí o sì dán mi wò,

dán àyà àti ọkàn mi wò;

3Nítorí ìfẹ́ ẹ̀ rẹ tí ó dúró ṣinṣin ń bẹ níwájú mi,

èmí sì ti rìn nínú òtítọ́ rẹ.

4Èmi kò jókòó pẹ̀lú aláìṣòótọ́,

bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò bá àwọn àgàbàgebè wọlé;

5Èmi ti kórìíra àwùjọ àwọn ènìyàn búburú

èmi kì yóò sì bá àwọn ènìyàn ìkà jókòó.

6Èmí ó wẹ ọwọ́ mi ní àìlẹ́ṣẹ̀,

bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò sì yí pẹpẹ rẹ ká Olúwa.

7Èmi yóò kọrin sókè àní orin ọpẹ́,

èmi yóò sì máa sọ iṣẹ́ ìyanu rẹ̀.

8Háà Olúwa, èmí ń fẹ́ ilé rẹ níbi tí ìwọ ń gbé,

àní níbi tí ògo rẹ̀ wà.

9Má ṣe gbá mi dànù pẹ̀lú àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀,

tàbí ẹ̀mí mi pẹ̀lú àwọn ọkùnrin tí òǹgbẹ ẹ̀jẹ̀ ń gbẹ,

10Àwọn tí ọwọ́ wọn kún fún ìwà ibi,

tí ọwọ́ ọ̀tún wọn kún fún àbẹ̀tẹ́lẹ̀.

11Ṣùgbọ́n èmi ó máa rìn nínú ìwà títọ́;

rà mí padà, kí o sì ṣàánú fún mi.

12Ẹsẹ̀ mi dúró lórí ilẹ̀ tí ó tẹ́jú;

nínú ìjọ ńlá èmi yóò fi ìbùkún fún Olúwa.