Zaburi 24 – NEN & YCB

Kiswahili Contemporary Version (Neno: Bibilia Takatifu)

Zaburi 24:1-10

Zaburi 24

Mfalme Mkuu

Zaburi ya Daudi.

124:1 Kut 9:29; Ay 41:11; 1Kor 10:26Dunia ni mali ya Bwana, na vyote vilivyomo ndani yake,

ulimwengu, na wote waishio ndani yake,

224:2 Za 104:3; Mwa 1:6; 2Pet 3:5maana aliiwekea misingi yake baharini

na kuifanya imara juu ya maji.

324:3 Za 2:6; 15:1; 65:4Nani awezaye kuupanda mlima wa Bwana?

Ni nani awezaye kusimama patakatifu pake?

424:4 2Sam 22:21; Za 51:10; 73:1; Mt 5:8; Eze 18:15Ni yule mwenye mikono safi na moyo mweupe,

yule ambaye hakuinulia sanamu nafsi yake

au kuapa kwa kitu cha uongo.

524:5 Kum 11:26; Za 17:2Huyo atapokea baraka kutoka kwa Bwana,

na hukumu ya haki kutoka kwa Mungu Mwokozi wake.

624:6 Za 27:8; 105:4; 119:58; Hos 5:15Hiki ndicho kizazi cha wale wamtafutao,

wale wautafutao uso wako, Ee Mungu wa Yakobo.

724:7 Isa 26:2; 60:11, 18; 62:10; Za 74:12; 29:3; 118:19, 20; 44:4; Mdo 7:2; 1Kor 2:8; Zek 9:9; Mt 21:5; Hag 2:7; Mal 3:1Inueni vichwa vyenu, enyi malango,

inukeni enyi milango ya kale,

ili mfalme wa utukufu apate kuingia.

824:8 1Nya 29:11; Za 89:13; Kum 4:34; Yer 50:34; Efe 6:10; Kut 15:3, 6Ni nani huyu Mfalme wa utukufu?

Ni Bwana aliye na nguvu na uweza,

ni Bwana aliye hodari katika vita.

9Inueni vichwa vyenu, enyi malango,

viinueni juu enyi milango ya kale,

ili Mfalme wa utukufu apate kuingia.

1024:10 1Sam 1:11Ni nani yeye, huyu Mfalme wa utukufu?

Ni Bwana Mwenye Nguvu Zote;

yeye ndiye Mfalme wa utukufu.

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 24:1-10

Saamu 24

Ti Dafidi. Saamu.

124.1: 1Kọ 10.26.Ti Olúwa ni ilẹ̀, àti ẹ̀kún rẹ̀,

ayé àti àwọn tí ó tẹ̀dó sínú rẹ̀;

2Nítorí ó fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ lélẹ̀ lórí Òkun

ó sì gbé e kalẹ̀ lórí àwọn ìṣàn omi.

3Ta ni yóò gun orí òkè Olúwa lọ?

Ta ni yóò dúró ní ibi mímọ́ rẹ̀?

424.4: Mt 5.8.Ẹni tí ó ní ọwọ́ mímọ́ àti àyà funfun,

ẹni tí kò gbé ọkàn rẹ̀ sókè sí asán

tí kò sì búra èké.

5Òun ni yóò rí ìbùkún gbà láti ọ̀dọ̀ Olúwa,

àti òdodo lọ́wọ́ Ọlọ́run ìgbàlà rẹ̀.

6Èyí ni ìran àwọn tí ń ṣe àfẹ́rí rẹ̀,

tí ń ṣe àfẹ́rí rẹ̀, Ọlọ́run Jakọbu. Sela.

7Ẹ gbé orí yín sókè, háà! Ẹ̀yin ọ̀nà;

Kí á sì gbe yín sókè, ẹyin ìlẹ̀kùn ayérayé!

Kí ọba ògo le è wọlé.

8Ta ni ọba ògo náà?

Olúwa tí ó lágbára tí ó sì le,

Olúwa gan an, tí ó lágbára ní ogun.

9Gbé orí yín sókè, ẹyin ọ̀nà;

kí a sì gbé e yín sókè, ẹ̀yin ìlẹ̀kùn ayérayé,

kí Ọba ògo le è wọlé wá.

10Ta ni Ọba ògo náà?

Olúwa àwọn ọmọ-ogun

Òun ni Ọba ògo náà. Sela.