ኤርምያስ 47 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

ኤርምያስ 47:1-7

ስለ ፍልስጥኤማውያን የተነገረ መልእክት

1ፈርዖን ጋዛን ድል ከማድረጉ በፊት፣ ስለ ፍልስጥኤማውያን ወደ ነቢዩ ወደ ኤርምያስ የመጣው የእግዚአብሔር ቃል ይህ ነው፤

2እግዚአብሔር እንዲህ ይላል፤

“እነሆ፤ በሰሜን በኩል ውሃ እየሞላ ነው፤

ኀይለኛ ጐርፍ ይሆናል፤

አገሪቷንና በውስጧ ያሉትንም ሁሉ፣

ከተሞቿንና ነዋሪዎቻቸውን ያጥለቀልቃል።

ሕዝቡም ድምፁን ከፍ አድርጎ ይጮኻል፤

የምድሪቱ ነዋሪ ሁሉ ዋይ ዋይ ይላል፤

3ከፈረስ ኮቴ ድምፅ፣

ከጠላት ሠረገላ ጩኸትና

ከሠረገላው ሽክርክሪት ፍትጊያ ድምፅ የተነሣ፣

አባቶች ልጆቻቸውን ለመርዳት ወደ ኋላ መለስ አይሉም፤

እጃቸውም ስንኩል ይሆናል።

4ፍልስጥኤማውያንን ሁሉ ለማጥፋት፣

ተርፈውም የሚረዷቸውን ሁሉ፣

ከጢሮስና ከሲዶና ለመቍረጥ፣

ቀኑ ደርሷልና።

እግዚአብሔር በከፍቶር47፥4 ቀርጤስ ነው ዳርቻ የቀሩትን፣ ፍልስጥኤማውያንን ሊያጠፋ

ተነሥቷል።

5ጋዛ በማዘን ራሷን ትላጫለች፤

አስቀሎና አፏን ትይዛለች።

በሜዳማ ስፍራ የምትገኙ ቅሬታዎች ሆይ፤

እስከ መቼ ሰውነታችሁን ትቧጥጣላችሁ?

6“ ‘የእግዚአብሔር ሰይፍ ሆይ፤

የማታርፈው እስከ መቼ ነው?

ወደ ሰገባህ ተመልሰህ ግባ፤

ጸጥ ብለህ ተቀመጥ’ ትላላችሁ።

7ነገር ግን እግዚአብሔር አስቀሎናንና የባሕሩን ዳርቻ፣

እንዲወጋ ሲያዝዘው፣

እንዲፈጽመውም ትእዛዝ ሲሰጠው፣

እንዴት ማረፍ ይችላል?”

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Jeremiah 47:1-7

Àṣọtẹ́lẹ̀ ní tí àwọn ará Filistini

147.1-7: Isa 14.29-31; El 25.15-17; Am 1.6-8; Sf 2.4-7; Sk 9.5-7.Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tó tọ wòlíì Jeremiah wá nípa àwọn Filistini, kí ó tó di pé Farao dojúkọ Gasa:

2Báyìí ni Olúwa wí:

“Wo bí omi ti ń ru sókè ní àríwá,

wọn ó di odò tí ń bo bèbè mọ́lẹ̀.

Wọn kò ní borí ilẹ̀ àti ohun gbogbo tó wà lórí rẹ̀,

ìlú àti àwọn tó ń gbé nínú wọn.

Àwọn ènìyàn yóò kígbe;

gbogbo olùgbé ilẹ̀ náà yóò hu

3Nígbà tí wọ́n bá gbọ́ ìró títẹ̀lé pátákò ẹsẹ̀ ẹṣin alágbára

nígbà tí wọ́n bá gbọ́ ariwo kẹ̀kẹ́ ogun ọ̀tá ńlá

àti iye kẹ̀kẹ́ wọn.

Àwọn baba kò ní lè ran àwọn ọmọ lọ́wọ́;

ọwọ́ wọn yóò kákò.

4Nítorí tí ọjọ́ náà ti pé

láti pa àwọn Filistini run,

kí a sì mú àwọn tí ó là

tí ó lè ran Tire àti Sidoni lọ́wọ́ kúrò.

Olúwa ti ṣetán láti pa Filistini run,

àwọn tí ó kù ní agbègbè Kafitori.

5Gasa yóò fá irun orí rẹ̀ nínú ọ̀fọ̀.

A ó pa Aṣkeloni lẹ́nu mọ́;

ìyókù ní pẹ̀tẹ́lẹ̀,

ìwọ yóò ti sá ara rẹ lọ́gbẹ́ pẹ́ tó?

6“Ẹ̀yin kígbe, ‘Yé è, idà Olúwa,

yóò ti pẹ́ tó tí ìwọ yóò sinmi?

Padà sínú àkọ̀ rẹ;

sinmi kí o sì dákẹ́ jẹ́ẹ́.’

7Ṣùgbọ́n báwo ni yóò ṣe sinmi,

nígbà tí Olúwa ti pàṣẹ fún un,

nígbà tí ó ti pa á láṣẹ

láti dojúkọ Aṣkeloni àti agbègbè rẹ̀.”