ኢዮብ 23 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

ኢዮብ 23:1-17

ኢዮብ

1ኢዮብም እንዲህ ሲል መለሰ፤

2“ዛሬም ሐዘኔ መራራ ነው፤

እያቃሰትሁ እንኳ እጁ23፥2 በሰብዓ ሊቃናት ትርጕም፣ በሱርስትና በዕብራይስጡ ላይ፣ እጅ በላዬ ይላል። በላዬ ከብዳለች።

3እርሱን የት እንደማገኘው ባወቅሁ፤

ወደ መኖሪያውም መሄድ በቻልሁ!

4ጕዳዬን በፊቱ አቀርብ ነበር፤

አፌንም በሙግት እሞላው ነበር።

5የሚመልስልኝ ቃል ምን እንደ ሆነ ባወቅሁ ነበር፤

የሚለኝንም ባስተዋልሁ ነበር።

6በታላቅ ኀይሉ ከእኔ ጋር ይሟገት ይሆን?

አይደለም፤ ይልቁን ያደምጠኛል።

7ቅን ሰው ጕዳዩን በእርሱ ፊት ያቀርባል፤

እኔም ከፈራጄ ለዘላለም ነጻ እሆናለሁ።

8“ዳሩ ግን ወደ ምሥራቅ ብሄድ፣ በዚያ የለም፤

ወደ ምዕራብም ብሄድ፣ እርሱን አላገኘውም፤

9በሰሜን እየሠራ ሳለ አላየውም፤

ወደ ደቡብ በሚዞርበት ጊዜ ደብዛው አይገኝም።

10ግን እኔ የምሄድበትን መንገድ ያውቃል፤

ከፈተነኝም በኋላ እንደ ወርቅ እወጣለሁ።

11እግሮቼ ርምጃውን በጥብቅ ተከታትለዋል፤

ፈቀቅ ሳልል መንገዱን ጠብቄአለሁ።

12ከአፉ ከወጣው ትእዛዝ አልራቅሁም፣

የአንደበቱን ቃል ከዕለት እንጀራዬ አብልጬ ይዣለሁ።

13“እርሱ ግን ራሱን ችሎ ብቻውን የሚኖር ነው፤ የሚቋቋመውስ ማን ነው?

እርሱ የፈቀደውን ያደርጋል።

14በእኔ ላይ የወሰነውን ይፈጽማል፤

ይህን የመሰለ ዕቅድም ገና ብዙ አለው።

15በፊቱ የደነገጥሁትም ለዚህ ነው፤

ይህን ሁሉ ሳስብ እፈራለሁ።

16እግዚአብሔር ልቤን አባባው፤

ሁሉንም የሚችል አምላክ አስደነገጠኝ።

17ይህም ሆኖ ሳለ ጨለማው፣

ፊቴንም የጋረደው ጽልመት ልሳኔን አልዘጋውም።

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Jobu 23:1-17

Èsì Jobu

1Ìgbà náà ni Jobu sì dáhùn wí pé:

2“Àní lónìí ni ọ̀ràn mi korò;

ọwọ́ mí sì wúwo sí ìkérora mi.

3Háà! èmi ìbá mọ ibi tí èmí ìbá wá

Ọlọ́run rí, kí èmí kí ó tọ̀ ọ́ lọ sí ibùgbé rẹ̀!

4Èmi ìbá sì to ọ̀ràn náà níwájú rẹ̀,

ẹnu mi ìbá sì kún fún àròyé.

5Èmi ìbá sì mọ ọ̀rọ̀ tí òun ìbá fi dá

mi lóhùn; òye ohun tí ìbáwí a sì yé mi.

6Yóò ha fi agbára ńlá bá mi wíjọ́ bí?

Àgbẹdọ̀, kìkì pé òun yóò sì kíyèsi mi.

7Níbẹ̀ ni olódodo le è bá a wíjọ́,

níwájú rẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò sì bọ́ ni ọwọ́ onídàájọ́ mi láéláé.

8“Sì wò ó, bí èmi bá lọ sí iwájú,

òun kò sí níbẹ̀, àti sí ẹ̀yìn, èmi kò sì rí òye rẹ̀:

9Ni apá òsì bí ó bá ṣiṣẹ́ níbẹ̀, èmi kò rí i,

ó fi ara rẹ̀ pamọ́ ni apá ọ̀tún, tí èmi kò le è rí i.

10Ṣùgbọ́n òun mọ ọ̀nà tí èmi ń tọ̀,

nígbà tí ó bá dán mí wò, èmi yóò jáde bí wúrà.

11Ẹsẹ̀ mí ti tẹ̀lé ipasẹ̀ ìrìn rẹ̀;

ọ̀nà rẹ̀ ni mo ti kíyèsi, tí ń kò sì yà kúrò.

12Bẹ́ẹ̀ ni èmi kò padà sẹ́yìn kúrò nínú òfin ẹnu rẹ̀,

èmi sì pa ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ mọ́ ju oúnjẹ òòjọ́ lọ.

13“Ṣùgbọ́n onínú kan ni òun, ta ni yóò sì yí i padà?

Èyí tí ọkàn rẹ̀ sì ti fẹ́, èyí náà ní í ṣe.

14Nítòótọ́ ohun tí a ti yàn fún mi ní í ṣe;

ọ̀pọ̀lọpọ̀ irú ohun bẹ́ẹ̀ ni ó wà ní ọwọ́ rẹ̀.

15Nítorí náà ni ara kò ṣe rọ̀ mí níwájú rẹ̀;

nígbà tí mo bá rò ó, ẹ̀rù a bà mi.

16Nítorí pé Ọlọ́run ti pá mi ní àyà,

Olódùmarè sì ń dààmú mi.

17Nítorí tí a kò tí ì ké mi kúrò níwájú òkùnkùn,

bẹ́ẹ̀ ni kò pa òkùnkùn biribiri mọ́ kúrò níwájú mi.