ኢዮብ 22 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

ኢዮብ 22:1-30

ኤልፋዝ

1ቴማናዊውም ኤልፋዝ እንዲህ ሲል መለሰ፤

2“ሰው እግዚአብሔርን ሊጠቅም ይችላልን?

ጠቢብ እንኳ ቢሆን ምን ይጠቅመዋል?

3አንተ ጻድቅ ብትሆን ሁሉን የሚችለውን አምላክ ምን ደስ ታሰኘዋለህ?

መንገድህ ያለ ነቀፋ ቢሆንስ የሚተርፈው ምንድን ነው?

4“እርሱ የሚገሥጽህ፣

ፍርድ ቤትም የሚያቀርብህ ስለምትፈራው ነውን?

5ክፋትህ ታላቅ፣

ኀጢአትህ ፍጻሜ የሌለው አይደለምን?

6ያለ አንዳች ምክንያት ከወንድሞችህ መያዣ ወስደሃል፤

ሰዎችን ገፍፈህ፣ ያለ ልብስ ዕራቍታቸውን አስቀርተሃል።

7የዛሉትን ውሃ አላጠጣህም፤

የተራቡትንም ምግብ ከልክለሃል።

8ባለ ርስትና ኀያል፣

በእርሱም የምትኖር ክቡር ሰው ብትሆንም፣

9መበለቶችን ባዶ እጃቸውን ሰድደሃል፤

የድኻ ዐደጎችንም ክንድ ሰብረሃል።

10ድንገተኛ አደጋ ያናወጠህ፣

ወጥመድም ዙሪያህን የከበበህ ለዚህ ነው።

11እንዳታይ ጨለማ የሆነብህ፣

ጐርፍም ያጥለቀለቀህ ለዚህ ነው።

12“እግዚአብሔር ከፍ ባለው ሰማይ የሚኖር አይደለምን?

በሩቅ ከፍታ ያሉትን ከዋክብት ያያል!

13ይህም ሆኖ ሳለ እንዲህ አልህ፤ ‘እግዚአብሔር ምን ያውቃል?

በእንዲህ ያለ ጨለማ ውስጥስ ይፈርዳልን?

14በሰማይ ክበብ ላይ ሲራመድ፣

እንዳያየን ጥቅጥቅ ያለ ደመና ይሸፍነዋል።’

15ኀጢአተኞች በሄዱባት፣

በጥንቷ መንገድ እንደ ተመላለስህ ትቀራለህን?

16ጊዜያቸው ሳይደርስ ተነጠቁ፤

መሠረታቸውም በጐርፍ ተወሰደ።

17እግዚአብሔርንም ‘አትድረስብን!

ሁሉን የሚችል አምላክም ምን ያደርግልናል?’ አሉ።

18ቤታቸውን በመልካም ነገር የሞላው ግን እርሱ ነው፤

ስለዚህ ከኀጢአተኞች ምድር እርቃለሁ።

19“ጻድቃንም የእነዚያን ጥፋት አይተው ይደሰታሉ፤

ንጹሓንም እንዲህ ብለው ያፌዙባቸዋል፤

20‘በርግጥ ጠላቶቻችን ጠፍተዋል፤

ሀብታቸውም በእሳት ተበልቷል።’

21“ለእግዚአብሔር ተገዛ፤ ከእርሱም ጋር ሰላም ይኑርህ፤

በረከትም ታገኛለህ።

22ምክርን ከአፉ ተቀበል፤

ቃሉንም በልብህ አኑር።

23ሁሉን ወደሚችል አምላክ ብትመለስ ትጠገናለህ፤

ክፋትን ከድንኳንህ ብታርቅ፣

24የወርቅህን አንኳር ትቢያ ላይ፣

የኦፊር ወርቅህንም ጥልቅ ሸለቆ ውስጥ ብትጥለው፣

25ሁሉን ቻዩ አምላክ ወርቅ ይሆንልሃል፤

ምርጥ ብር ይሆንልሃል።

26በዚያ ጊዜ ሁሉን በሚችል አምላክ ደስ ይልሃል፤

ፊትህንም ወደ እግዚአብሔር ታቀናለህ።

27ወደ እርሱ ትጸልያለህ፤ እርሱም ይሰማሃል፤

አንተም ስእለትህን ትሰጣለህ።

28ያሰብኸው ይከናወንልሃል፤

በመንገድህም ላይ ብርሃን ይበራል።

29ሰዎች ቢዋረዱና አንተ፣ ‘ከፍ አድርጋቸው’ ብትል፣

እርሱ ዝቅ ያሉትን ያድናል፤

30በጎ ያልሆነውን ሰው እንኳ፣

ከአንተ እጅ ንጽሕና የተነሣ ያድነዋል።”

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Jobu 22:1-30

Èsì Elifasi

1Ìgbà náà ni Elifasi, ará Temani, dáhùn wí pé:

222.2,3: Jb 35.6-8.“Ènìyàn lè è ṣe rere fún Ọlọ́run?

Bí ọlọ́gbọ́n ti í ṣe rere fún ara rẹ̀?

3Ohun ayọ̀ ha ni fún Olódùmarè pé olódodo ni ìwọ?

Tàbí èrè kí ni fún un ti ìwọ mú ọ̀nà rẹ̀ pé?

4“Yóò ha bá ọ wí bí, nítorí ìbẹ̀rù

Ọlọ́run rẹ? Yóò ha bá ọ lọ sínú ìdájọ́ bí?

5Ìwà búburú rẹ kò ha tóbi,

àti ẹ̀ṣẹ̀ rẹ láìníye?

6Nítòótọ́ ìwọ béèrè fún ààbò ni ọwọ́ arákùnrin rẹ láìnídìí,

ìwọ sì tú oníhòhò ní aṣọ wọn.

7Ìwọ kò fi omi fún aláàárẹ̀ mu,

ìwọ sì háwọ́ oúnjẹ fún ẹni tí ebi ń pa.

8Bí ó ṣe ti alágbára nì, òun ni ó ní ilẹ̀,

ọlọ́lá sì tẹ̀dó sínú rẹ̀.

9Ìwọ ti rán àwọn opó padà lọ ní ọwọ́ òfo;

Apá àwọn ọmọ aláìní baba ti di ṣiṣẹ́.

10Nítorí náà ni ìdẹ̀kùn ṣe yí ọ káàkiri,

àti ìbẹ̀rù òjijì ń yọ ọ́ lẹ́nu,

11Èéṣe tí òkùnkùn fi pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ tí ìwọ kò fi lè ríran;

Èéṣe tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ omi sì bò ọ́ mọ́lẹ̀.

12“Ọlọ́run kò ha jẹ́ ẹni gíga ọ̀run?

Sá wo orí àwọn ìràwọ̀ bí wọ́n ti ga tó!

13Ìwọ sì wí pé, Ọlọ́run ti ṣe mọ̀?

Òun ha lè ṣe ìdájọ́ láti inú òkùnkùn wá bí?

14Ǹjẹ́ àwọsánmọ̀ tí ó nípọn jẹ ìbora fún un,

tí kò fi lè ríran; ó sì ń rìn nínú àyíká ọ̀run.

15Ǹjẹ́ ìwọ fẹ́ rin ipa ọ̀nà ìgbàanì tí àwọn

ènìyàn búburú tí rìn?

16A ké wọn lulẹ̀ kúrò nínú ayé láìpé ọjọ́ wọn;

ìpìlẹ̀ wọn ti da bí odò ṣíṣàn;

17Àwọn ẹni tí ó wí fún Ọlọ́run pé, ‘Lọ kúrò lọ́dọ̀ wa!

Kí ni Olódùmarè yóò ṣe fún wọn?’

18Síbẹ̀ ó fi ohun rere kún ilé wọn!

Ṣùgbọ́n ìmọ̀ ènìyàn búburú jìnnà sí mi!

19Àwọn olódodo rí ìparun wọn, wọ́n sì yọ̀,

àwọn aláìlẹ́ṣẹ̀ sì fi wọ́n rẹ́rìn-ín ẹlẹ́yà pé,

20‘Lóòtítọ́ àwọn ọ̀tá wa ni a ké kúrò,

iná yóò sì jó oró wọn run.’

21“Fa ara rẹ súnmọ́ Ọlọ́run, ìwọ ó sì rí àlàáfíà;

nípa èyí ni rere yóò wá bá ọ.

22Èmi bẹ̀ ọ́, gba òfin láti ẹnu rẹ̀ wá,

kí o sì to ọ̀rọ̀ rẹ̀ sí àyà rẹ.

23Bí ìwọ bá yípadà sọ́dọ̀ Olódùmarè, a sì gbé ọ ró:

Bí ìwọ bá sì mú ẹ̀ṣẹ̀ jìnnà réré kúrò nínú àgọ́ rẹ,

24Tí ìwọ bá tẹ́ wúrà dáradára sílẹ̀

lórí erùpẹ̀ àti wúrà ofiri lábẹ́ òkúta odò,

25Nígbà náà ní Olódùmarè yóò jẹ́ wúrà rẹ,

àní yóò sì jẹ́ fàdákà fún ọ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀.

26Lóòtítọ́ nígbà náà ní ìwọ ó ní inú dídùn nínú Olódùmarè,

ìwọ ó sì gbé ojú rẹ sókè sọ́dọ̀ Ọlọ́run.

27Bí ìwọ bá gbàdúrà rẹ sọ́dọ̀ rẹ̀, yóò sì gbọ́ tìrẹ,

ìwọ ó sì san ẹ̀jẹ́ rẹ.

28Ìwọ ó sì gbìmọ̀ ohun kan pẹ̀lú, yóò sì fi ìdí múlẹ̀ fún ọ;

ìmọ́lẹ̀ yóò sì mọ́ sípa ọ̀nà rẹ.

29Nígbà tí ipa ọ̀nà rẹ bá lọ sísàlẹ̀,

nígbà náà ni ìwọ o wí pé, ‘Ìgbésókè ń bẹ!’

Ọlọ́run yóò sì gba onírẹ̀lẹ̀ là!

30Yóò gba ẹni tí kì í ṣe aláìjẹ̀bi là,

a ó sì gbà á nípa mímọ́ ọwọ́ rẹ̀.”