ኢዮብ 21 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

ኢዮብ 21:1-34

ኢዮብ

1ኢዮብም እንዲህ ሲል መለሰ፤

2“ቃሌን በጥንቃቄ ስሙ፤

የምታጽናኑኝም በዚህ ይሁን፤

3ንግግሬን በትዕግሥት አድምጡ፤

ከተናገርሁ በኋላ፣ መሣለቅ ትችላላችሁ።

4“በውኑ ቅርታዬ በሰው ላይ ነውን?

ትዕግሥት ማጣትስ አይገባኝምን?

5ተመልከቱኝና ተገረሙ፤

አፋችሁን በእጃችሁ ለጕሙ።

6ስለዚህ ነገር ባሰብሁ ቍጥር እደነግጣለሁ፤

ሰውነቴም በፍርሀት ይንቀጠቀጣል።

7ኀጢአተኞች ለምን በሕይወት ይኖራሉ?

ለምን ለእርጅና ይበቃሉ? ለምንስ እያየሉ ይሄዳሉ?

8ዘራቸው በዐይናቸው ፊት፣

ልጆቻቸውም በዙሪያቸው ጸንተው ሲኖሩ ያያሉ፤

9ቤታቸው ያለ ሥጋት በሰላም ይኖራል፤

የእግዚአብሔርም በትር የለባቸውም።

10ኮርማቸው ዘሩ በከንቱ አይወድቅም፤

ያስረግዛል፤ ላማቸውም ሳትጨነግፍ ትወልዳለች።

11ልጆቻቸውን እንደ በግ መንጋ ያሰማራሉ፤

ሕፃናታቸውም ይቦርቃሉ።

12በከበሮና በክራር ይዘፍናሉ፤

በዋሽንትም ድምፅ ይፈነጫሉ።

13ዕድሜያቸውን በተድላ ያሳልፋሉ፤

በሰላምም21፥13 ወይም በፍጥነት ማለት ነው። ወደ መቃብር21፥13 በዕብራይስጡ፣ ሲኦል ይላል። ይወርዳሉ።

14እግዚአብሔርንም እንዲህ ይሉታል፤ ‘አትድረስብን!

መንገድህንም ማወቅ አንፈልግም።

15እናገለግለው ዘንድ፣ ሁሉን ቻይ አምላክ ማን ነው?

ወደ እርሱ ብንጸልይስ ምን እናገኛለን?’

16ይሁንና ብልጽግናቸው በእጃቸው አይደለም፤

ከኀጢአተኞች ምክር እርቃለሁ።

17“የኀጢአተኞች መብራት የጠፋው ስንት ጊዜ ነው?

የእግዚአብሔር ቍጣ መከራ የመጣባቸው፣

መቅሠፍትም የደረሰባቸው ስንት ጊዜ ነው?

18በነፋስ ፊት እንዳለ ገለባ፣

በዐውሎ ነፋስም እንደ ተወሰደ ዕብቅ የሆኑት ስንት ጊዜ ነው?

19እናንተ፣ ‘እግዚአብሔር የሰውን ቅጣት ለልጆቹ ያከማቻል’ ትላላችሁ፤

ነገር ግን ያውቀው ዘንድ ለሰውየው ለራሱ ይክፈለው፤

20ዐይኖቹ የራሱን ውድቀት ይዩ፤

ሁሉን ከሚችል አምላክ21፥17-20 17፡18 ቃለ አጋኖዎች ሲሆኑ፣ 19፡20 ደግሞ ብያኔዎች ናቸው። ቍጣ ይጠጣ።

21ሰው ወራቱ በተገባደደ ጊዜ፣

ለቀሪ ቤተ ሰቡ ምን ይገድደዋል?

22“ከፍ ባሉት ላይ ለሚፈርድ አምላክ፣

ዕውቀትን ሊያስተምረው የሚችል አለን?

23አንድ ሰው በፍጹም ተድላ ደስታ እየኖረ፣

በሙሉ ብርታቱም እያለ ይሞታል፤

24ሰውነቱ21፥24 የዚህ ቃል የዕብራይስጡ ትርጕም በትክክል አይታወቅም። በምቾት፣

ዐጥንቱም በሥብ ተሞልቶ እያለ በሞት ይለያል።

25ሌላው ሰው ደግሞ አንዳች መልካም ነገር ሳያይ፣

በተመረረች ነፍስ ይሞታል፤

26ሁለቱም በዐፈር ውስጥ አንድ ላይ ይተኛሉ፤

ትልም ይወርሳቸዋል።

27“እነሆ፣ ምክራችሁን፣

በእኔ ላይ ያሤራችሁትንም ተረድቻለሁ።

28እናንተ፣ ‘የትልቁ ሰው ቤት፣

ኀጢአተኛውም የኖረበት ድንኳን የት አለ?’ አላችሁ፤

29መንገደኞችን አልጠየቃችሁምን?

የነገሯችሁንስ ነገር በጥሞና አላዳመጣችሁምን?

30ክፉ ሰው በመቅሠፍት ቀን እንደሚጠበቅ፣

በቍጣም ቀን እንደሚተርፍ21፥30 ወይም ለመቅሠፍት ቀን ተጠብቆ እንደሚቈይ ማለት ነው። አታውቁምን?

31ተግባሩን ፊት ለፊት የሚነግረው ማን ነው?

የእጁንስ ማን ይሰጠዋል?

32ወደ መቃብር ይወስዱታል፤

ለመቃብሩም ጠባቂ ይደረግለታል።

33የሸለቈው ዐፈር ምቹ ይሆንለታል፤

ሰው ሁሉ ይከተለዋል፤

ስፍር ቍጥር የሌለው ሕዝብ21፥33 ወይም ስፍር ቍጥር እንደ ሌለው ሕዝብ ማለት ነው። በፊቱ ይሄዳል።

34“መልሳችሁ ከሐሰት በስተቀር ሌላ አይገኝበትም!

ታዲያ፣ በማይረባ ነገር እንዴት ልታጽናኑኝ ትችላላችሁ?”

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Jobu 21:1-34

Jobu dá Sofari lóhùn

1Jobu wá dáhùn, ó sì wí pé:

2“Ẹ tẹ́tí sílẹ̀ dáradára sì àwọn ọ̀rọ̀ mi,

kí èyí kí ó jásí ìtùnú fún mi.

3Ẹ jọ̀wọ́ mi ki èmi sọ̀rọ̀; lẹ́yìn ìgbà

ìwọ le máa fi mi ṣẹ̀sín ń ṣo.

4“Àròyé mi ha ṣe sí ènìyàn bí?

Èétise tí ọkàn mi kì yóò fi ṣe àìbalẹ̀?

5Ẹ wò mí fín, kí ẹnu kí ó sì yà yín,

kí ẹ sì fi ọwọ́ lé ẹnu yín.

6Àní nígbà tí mo rántí, ẹ̀rù bà mí,

ìwárìrì sì mú mi lára.

7Nítorí kí ní ènìyàn búburú fi wà ní

ayé, tí wọ́n gbó, àní tí wọ́n di alágbára ní ipa?

8Irú-ọmọ wọn fi ìdí kalẹ̀ ní ojú

wọn pẹ̀lú wọn, àti ọmọ ọmọ wọn ní ojú wọn.

9Ilé wọn wà láìní ewu àti ẹ̀rù, bẹ́ẹ̀

ni ọ̀pá ìbínú Ọlọ́run kò sí lára wọn.

10Akọ màlúù wọn a máa gùn, kì í sì

tàsé; abo màlúù wọn a máa bí, kì í sì í ṣẹ́yun;

11Wọn a máa rán àwọn ọmọ wọn

wẹ́wẹ́ jáde bí agbo ẹran, àwọn ọmọ wọn a sì máa jo kiri.

12Wọ́n mú ohun ọ̀nà orin, ìlù àti

haapu, wọ́n sì ń yọ̀ sí ohùn fèrè.

13Wọ́n n lo ọjọ́ wọn nínú ọrọ̀; wọn

sì lọ sí ipò òkú ní àlàáfíà.

14Nítorí náà ni wọ́n ṣe wí fún Ọlọ́run pé, ‘Lọ kúrò lọ́dọ̀ wa!’

Nítorí pé wọn kò fẹ́ ìmọ̀ ipa ọ̀nà rẹ.

15Kí ni Olódùmarè tí àwa ó fi máa sìn in?

Èrè kí ni a ó sì jẹ bí àwa ba gbàdúrà sí i?

16Kíyèsi i, àlàáfíà wọn kò sí nípa

ọwọ́ wọn; ìmọ̀ ènìyàn búburú jìnnà sí mi réré.

17“Ìgbà mélòó mélòó ní a ń pa fìtílà ènìyàn búburú kú?

Ìgbà mélòó mélòó ní ìparun wọn dé bá wọn,

tí Ọlọ́run sì í máa pín ìbìnújẹ́ nínú ìbínú rẹ̀?

18Wọ́n dàbí àgékù koríko níwájú afẹ́fẹ́,

àti bí ìyàngbò, tí ẹ̀fúùfù ńlá fẹ́ lọ.

19Ẹ̀yin wí pé, ‘Ọlọ́run to ìyà ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ jọ fún àwọn ọmọ rẹ̀.’

Jẹ́ kí ó san án fún un, yóò sì mọ̀ ọ́n.

20Ojú rẹ̀ yóò rí ìparun ara rẹ̀,

yóò sì máa mu nínú ríru ìbínú Olódùmarè.

21Nítorí pé àlàáfíà kí ni ó ní nínú ilé rẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀,

nígbà tí a bá ké iye oṣù rẹ̀ kúrò ní agbede-méjì?

22“Ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni le kọ Ọlọ́run ní ìmọ̀?

Òun ní í sá à ń ṣe ìdájọ́ ẹni ibi gíga.

23Ẹnìkan a kú nínú pípé agbára rẹ̀,

ó wà nínú ìrora àti ìdákẹ́ pátápátá.

24Ọpọ́n rẹ̀ kún fún omi ọmú,

egungun rẹ̀ sì tutù fún ọ̀rá.

25Ẹlòmíràn a sì kú nínú kíkorò ọkàn rẹ̀,

tí kò sì fi inú dídùn jẹun.

26Wọ́n o dùbúlẹ̀ bákan náà nínú erùpẹ̀,

kòkòrò yóò sì ṣùbò wọ́n.

27“Kíyèsi i, èmi mọ̀ èrò inú yín àti

àrékérekè ọkàn yín láti ṣe ìlòdì sí mi.

28Nítorí tí ẹ̀yin wí pé, ‘Níbo ní ilé ọmọ-aládé,

àti níbo ní àgọ́ àwọn ènìyàn búburú nì gbé wà?’

29Ẹ̀yin kò béèrè lọ́wọ́ àwọn tí ń kọjá lọ ní ọ̀nà?

Ẹ̀yin kò mọ̀ ààmì wọn, pé

30ènìyàn búburú ní a fi pamọ́ fún ọjọ́ ìparun.

A ó sì mú wọn jáde ní ọjọ́ ríru ìbínú.

31Ta ni yóò tako ipa ọ̀nà rẹ̀ lójúkojú,

ta ni yóò sì san án padà fún un ní èyí tí ó ti ṣe?

32Síbẹ̀ a ó sì sin ín ní ọ̀nà ipò òkú,

a ó sì máa ṣọ́ ibojì òkú.

33Ògúlùtu àfonífojì yóò dùn mọ́ ọn.

Gbogbo ènìyàn yóò sì máa tọ̀ ọ́

lẹ́yìn, bí ènìyàn àìníye ti lọ síwájú rẹ̀.

34“Èéha ti ṣe tí ẹ̀yin fi ń tù mí nínú lásán,

bí ò ṣe pé ní ìdáhùn yín, àrékérekè wa níbẹ̀!”