ኢሳይያስ 29 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

ኢሳይያስ 29:1-24

ወዮ ለዳዊት ከተማ

1ዳዊት የሰፈረብሽ ከተማ፣

አርኤል፣ አርኤል ወዮልሽ!

ዓመት በዓመት ላይ ጨምሪ፣

ዐውደ ዓመትሽም ይቀጥል።

2ነገር ግን አርኤልን29፥2 በዕብራይስጡ፣ የመሠዊያ መሬት የሚለው ቃል ድምፀት፣ አርኤል ከሚለው ቃል ጋር አንድ ዐይነት ነው። እከብባለሁ፤

ታለቅሳለች፤ ዋይ ዋይ ትላለች፤

ለእኔም እንደ መሠዊያ ስፍራ ትሆንልኛለች።

3በዙሪያሽ እሰፍራለሁ፤

በቅጥር እከብብሻለሁ፤

የከበባ ዐምባም ሠርቼ አስጨንቅሻለሁ።

4ወደ ታች ትወርጃለሽ፤ ከምድርም በታች ትናገሪያለሽ፤

ንግግርሽ ከትቢያ እየተጕተመተመ ይወጣል፤

ድምፅሽ እንደ መናፍስት ድምፅ ከመሬት ወደ ላይ ይመጣል፤

ንግግርሽ ከትቢያ ያንሾካሹካል።

5ነገር ግን ብዙ ጠላቶችሽ እንደ ትቢያ ብናኝ፣

የጨካኞች መንጋ በነፋስ እንደሚነዳ

ገለባ ይሆናሉ።

ድንገት ሳይታሰብም፣

6የሰራዊት ጌታ እግዚአብሔር

በነጐድጓድ፣ በምድር መናወጥና በታላቅ ድምፅ፣

በዐውሎ ነፋስና በኀይለኛ ሞገድ፣ ፈጽሞ በሚባላም የእሳት ነበልባል ይመጣል።

7አርኤልን የሚወጋ የአሕዛብ ሁሉ መንጋ፣

በእርሷና በምሽጓ ላይ አደጋ የሚጥልና የሚከብባት፣

እንደ ሕልም

በሌሊትም እንደሚታይ ራእይ ይሆናል።

8የተራበ ሰው በሕልሙ ሲበላ ዐድሮ፣

ነገር ግን ሲነቃ ራቡ እንዳልለቀቀው፣

የጠማውም ሰው በሕልሙ ሲጠጣ ዐድሮ፣

ነገር ግን ሲነቃ እንደ ዛለና ጥማቱም እንዳልተወው፣

የጽዮንን ተራራ የሚወጋ፣

የአሕዛብ መንጋ ሁሉ እንዲሁ ይሆናል።

9ነኹልሉ ተደነቁም፤

ተጨፈኑ፤ እስከ ወዲያኛውም ታውራችሁ ቅሩ፤

በወይን ጠጅ አይሁን እንጂ ስከሩ፤

በሚያሰክር መጠጥ አይሁን እንጂ ተንገዳገዱ።

10እግዚአብሔር ከባድ እንቅልፍ ጥሎባችኋል፤

ዐይኖቻችሁን፣ ነቢያትን ጨፍኖባችኋል፤

ራሶቻችሁን፣ ባለ ራእዮችን ሸፍኖባችኋል።

11ይህ ሁሉ ራእይ በጥቅልል መጽሐፍ ውስጥ እንደ ታሸገ ቃል ሆኖባችኋል። ጥቅልሉንም መጽሐፍ ማንበብ ለሚችል ሰው፣ “እባክህ አንብብልን” ብላችሁ ብትሰጡት፣ “ታሽጓልና አልችልም” ይላችኋል። 12ደግሞም ጥቅልሉን መጽሐፍ ማንበብ ለማይችል ሰው፣ “እባክህን አንብብልን” ብላችሁ ብትሰጡ፣ “ማንበብ አልችልም” ይላችኋል።

13እግዚአብሔር እንዲህ ይላል፤

“ይህ ሕዝብ በአፉ ወደ እኔ ይቀርባል፤

በከንፈሩም ያከብረኛል፤

ልቡ ግን ከእኔ የራቀ ነው፤

የሚያመልከኝም፣

ሰው ባስተማረው ሰው ሠራሽ ሥርዐት ብቻ ነው29፥13 ዕብራይስጡ ከዚህ ጋር ይስማማል፤ የሰብዓ ሊቃናት ትርጕም ግን፣ በከንቱ ያመልኩኛል፤ ትምህርታቸው ሰው ያሰተማረው ሰው ሠራሽ ሥርዐት ብቻ ነው ይላል።

14ስለዚህ ይህን ሕዝብ በድንቅ ላይ ድንቅ

ነገር እያደረግሁ፣

ዳግመኛ አስገርመዋለሁ፤

የጥበበኞች ጥበብ ይጠፋል፤

የአስተዋዮችም ማስተዋል ይበንናል።”

15ሐሳባቸውን ከእግዚአብሔር ለመደበቅ፣

ወደ ጥልቅ ጕድጓድ ለሚወርዱ

ሥራቸውንም በጨለማ ለሚያከናውኑ፣

“ማን ያየናል? ማንስ ያውቅብናል” ለሚሉ ወዮላቸው!

16እናንተ ነገሮችን ትገለብጣላችሁ

ሸክላ ሠሪውን እንደ ሸክላ ትመለከታላችሁ፤

ለመሆኑ፣ ተሠሪ ሠሪውን፣

“እርሱ አልሠራኝም” ይለዋልን?

ሸክላ የሠራውን፣

“እርሱ ምንም አያውቅም” ይለዋልን?

17ሊባኖስ ወደ ለም ዕርሻነት ለመለወጥ፣

ለም የሆነውም መሬት ወደ ዱርነት ለመለወጥ ጥቂት ጊዜ አልቀረውምን?

18በዚያን ጊዜ ደንቈሮ የጥቅልሉን መጽሐፍ ቃል ይሰማል፤

የዐይነ ስውሩም ዐይኖች

ከጭጋግና ከጨለማ ተላቀው ያያሉ።

19ትሑታን በእግዚአብሔር

ምስኪኖችም በእስራኤል ቅዱስ እንደ ገና ሐሤት ያደርጋሉ።

20ጨካኞች እንዳልነበሩ ይሆናሉ፤

ፌዘኞችም በንነው ይጠፋሉ፤

ለክፋት ያደፈጡ ሁሉ ይወገዳሉ።

21ሰውን በነገር በደለኛ የሚያደርጉ፣

በተከሳሽ ላይ ወጥመድ የሚዘረጉ፣

በሐሰት ምስክር ፍትሕን ከንጹሓን የሚቀሙ ይቈረጣሉ።

22ስለዚህ አብርሃምን የተቤዠው እግዚአብሔር

ለያዕቆብ ቤት እንዲህ ይላል፤

“ያዕቆብ ከእንግዲህ ወዲያ አያፍርም፤

ፊቱም ከእንግዲህ አይለዋወጥም።

23በመካከላቸው የእጄ ሥራ የሆኑ፣

ልጆቻቸውን ሲያዩ፣

ስሜን ይቀድሳሉ፤

የያዕቆብን ቅዱስ ቅድስና ያውቃሉ፤

በእስራኤልም አምላክ ፊት በፍርሀት ይቆማሉ።

24በመንፈስ የሳቱ ያስተውላሉ፤

የሚያጕረመርሙም ምክር ይቀበላሉ።”

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Isaiah 29:1-24

Ègbé ni fún ìlú Dafidi

1Ègbé ni fún ọ, Arieli, Arieli,

ìlú níbi tí Dafidi tẹ̀dó sí!

Fi ọdún kún ọdún

sì jẹ́ kí àwọn àkọlùkọgbà àjọ̀dún un rẹ tẹ̀síwájú.

2Síbẹ̀síbẹ̀ èmi yóò dó ti Arieli

òun yóò ṣọ̀fọ̀ yóò sì sọkún,

òun yóò sì dàbí pẹpẹ ọkàn sí mi.

3Èmi yóò sì wà ní bùba yí ọ ká níbi gbogbo;

Èmi yóò sì fi ilé ìṣọ́ yí ọ ká:

èmi yóò sì fi iṣẹ́ ìdó ti ni mi dojúkọ ọ́.

4Ní ìrẹ̀sílẹ̀, ìwọ ó sì máa sọ̀rọ̀ láti ilẹ̀ wá;

ọ̀rọ̀ rẹ yóò sì máa kùn jáde láti inú erùpẹ̀.

Ohun rẹ yóò máa jáde bí i ti ẹnìkan tó ní ẹ̀mí àfọ̀ṣẹ láti ilẹ̀ jáde wá,

láti inú erùpẹ̀ ni ohùn rẹ

yóò máa wá wúyẹ́wúyẹ́.

5Ṣùgbọ́n àwọn ọ̀tá rẹ, yóò dàbí yanrìn kíkúnná,

agbo àwọn aláìláàánú bí ìyàngbò tí a fẹ́ dànù.

Lójijì, ní ìṣẹ́jú kan,

6Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò wá

pẹ̀lú àrá, ilẹ̀-rírì àti ariwo ńlá

àti ẹ̀fúùfù líle àti iná ajónirun

7Lẹ́yìn náà,

ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ ènìyàn tí gbogbo orílẹ̀-èdè tí ó bá Arieli jà,

tí ó dojú ìjà kọ òun àti ilé olódi rẹ̀

tí ó sì dó tì í,

yóò dàbí ẹni pé nínú àlá,

bí ìran ní òru

8àti bí ìgbà tí ẹni tí ebi ń pa ń lá àlá pé òun ń jẹun,

ṣùgbọ́n ó jí, ebi rẹ̀ sì wà pẹ̀lú rẹ̀;

tàbí bí ìgbà tí ẹni tí òǹgbẹ ń gbẹ lá àlá pé òun ń mu omi,

ṣùgbọ́n nígbà tí ó jí, sì wò ó, ó dákú, òǹgbẹ sì ń gbẹ ọkàn rẹ̀.

Bẹ́ẹ̀ ni yóò sì rí fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè

tí ń bá òkè Sioni jà.

9Ẹ bẹ̀rù kí ẹnu kí ó yà yín,

ẹ fọ́ ara yín lójú kí ẹ má sì ríran;

ẹ mutí yó kì í ṣe ọtí wáìnì,

ẹ ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n, ṣùgbọ́n kì í ṣe ti ọtí líle.

10Olúwa ti mú oorun ìjìká wá sórí i yín:

ó ti dì yín lójú ẹ̀yin wòlíì;

ó ti bo orí yín ẹ̀yin aríran.

11Fún un yín gbogbo ìran yìí kò yàtọ̀ sí àwọn ọ̀rọ̀ tí a fi èdìdì dì sínú ìwé kíká. Bí ẹ bá sì fún ẹni tí ó lè ka ìwé kíká náà, tí ẹ sì sọ fún un pé, “Jọ̀wọ́ ka èyí,” òun yóò dáhùn pé, “Èmi kò lè kà á; a ti dì í ní èdìdì.” 12Tàbí bí ẹ bá fún ẹni tí kò lè ka ìwé kíká náà tí ẹ sì sọ pé, “Jọ̀wọ́ ka èyí,” òun yóò dáhùn pé, “Èmi kò mọ̀ ọ́n kà.”

1329.13: Mt 15.8-9; Mk 7.6-7.Olúwa wí pé:

“Àwọn ènìyàn yìí súnmọ́ ọ̀dọ̀ mi pẹ̀lú ẹnu wọn,

wọ́n sì bọ̀wọ̀ fún mi pẹ̀lú ètè wọn,

ṣùgbọ́n ọkàn wọn jìnnà sí mi.

Ìsìn wọn si mi

ni a gbé ka orí òfin tí àwọn

ọkùnrin kọ́ ni.

1429.14: 1Kọ 1.19.Nítorí náà lẹ́ẹ̀kan sí i èmi yóò ya

àwọn ènìyàn yìí lẹ́nu

pẹ̀lú ìyanu lórí ìyanu;

ọgbọ́n àwọn ọlọ́gbọ́n ni yóò ṣègbé,

ìmọ̀ àwọn onímọ̀ ni yóò pòórá.”

15Ègbé ni fún àwọn tí ó lọ sí ọ̀gbun

láti fi ètò wọn pamọ́ kúrò lójú Olúwa,

tí wọ́n ń ṣe iṣẹ́ ẹ wọn nínú òkùnkùn

tí wọ́n sì rò pé,

“Ta ló rí wa? Ta ni yóò mọ̀?”

1629.16: Isa 45.9; Ro 9.20.Ẹ̀yin dojú nǹkan délẹ̀,

bí ẹni pé wọ́n rò pé amọ̀kòkò dàbí amọ̀!

Ǹjẹ́ ohun tí a ṣe le sọ fún olùṣe pé

“Òun kọ́ ló ṣe mí”?

Ǹjẹ́ ìkòkò lè sọ nípa amọ̀kòkò pé,

“kò mọ nǹkan”?

17Ní àìpẹ́ jọjọ, ǹjẹ́

a kò ní sọ Lebanoni di pápá ẹlẹ́tù lójú

àti pápá ẹlẹ́tù lójú yóò dàbí aginjù?

1829.18-19: Mt 11.5.Ní ọjọ́ náà adití yóò gbọ́ ọ̀rọ̀ ìwé kíká náà,

láti inú fìrífìrí àti òkùnkùn

ni àwọn ojú afọ́jú yóò ríran.

19Lẹ́ẹ̀kan sí i àwọn onírẹ̀lẹ̀ yóò yọ̀ nínú Olúwa:

àwọn aláìní yóò yọ̀ nínú Ẹni Mímọ́ ti Israẹli.

20Aláìláàánú yóò pòórá,

àwọn tí ń ṣẹlẹ́yà yóò di àwátì,

gbogbo àwọn tí ó ní ojú ibi ni a ó ké lulẹ̀—

21àwọn tí wọ́n fi ọ̀rọ̀ kan mú ẹnìkan di ẹlẹ́bi,

ẹni tí ń dẹkùn mú olùgbèjà ní ilé ẹjọ́

tí ẹ fi ẹ̀rí èké dun aláìṣẹ̀ ní ìdájọ́.

22Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa, ẹni tí ó ra Abrahamu padà sọ sí ilé Jakọbu:

“Ojú kì yóò ti Jakọbu mọ́;

ojú wọn kì yóò sì rẹ̀wẹ̀sì mọ́.

23Nígbà tí wọ́n bá rí i láàrín àwọn ọmọ wọn,

àwọn iṣẹ́ ọwọ́ mi,

wọn yóò ya orúkọ mi sí mímọ́,

wọn yóò tẹ́wọ́gbà mímọ́ Ẹni Mímọ́ Jakọbu

wọn yóò dìde dúró ní ìbọ̀wọ̀ fún Ọlọ́run Israẹli.

24Gbogbo àwọn tí ń rìn ségesège ní yóò jèrè ìmọ̀;

gbogbo àwọn tí ń ṣe àròyé yóò gba ìtọ́sọ́nà.”