ምሳሌ 7 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

ምሳሌ 7:1-27

ከአመንዝራ ሴት መራቅ

1ልጄ ሆይ፤ ቃሌን ጠብቅ፤

ትእዛዜንም በውስጥህ አኑር።

2ትእዛዜን ጠብቅ፤ በሕይወት ትኖራለህ፤

ትምህርቴንም እንደ ዐይንህ ብሌን ተንከባከበው።

3በጣትህ ላይ እሰረው፤

በልብህ ጽላት ላይ ጻፈው።

4ጥበብን፣ “እኅቴ ነሽ” በላት፤

ማስተዋልንም፣ “ዘመዴ ነህ” በለው፤

5ከአመንዝራ ሴት፣

በአንደበቷም ከምታታልል ዘልዛላ ሴት ይጠብቁሃል።

6በቤቴ መስኮት፣

በዐይነ ርግቡ ወደ ውጭ ተመለከትሁ።

7ማስተዋል የጐደለውን ወጣት፣

ብስለት ከሌላቸው መካከል አየሁት፤

ከጕልማሶችም መካከል ለየሁት።

8የቤቷን አቅጣጫ ይዞ፣

በቤቷ ማእዘን አጠገብ ባለው መንገድ ያልፍ ነበር፤

9ቀኑ መሸትሸት ሲል፣

በውድቅት ሌሊት፣ በጽኑ ጨለማ።

10ከዚያም አንዲት ሴት ልታገኘው ወጣች፤

እንደ ዝሙት ዐዳሪ ለብሳ፣ ለማሳሳት ታጥቃ።

11ጯኺና ማን አለብኝ ባይ ናት፤

እግሮቿ ዐርፈው ቤት አይቀመጡም፤

12አንዴ በመንገድ፣ አንዴ በአደባባይ፣

በየማእዘኑም ታደባለች።

13አፈፍ አድርጋ ይዛ ሳመችው፤

ኀፍረቷንም ጥላ እንዲህ አለችው፤

14“በቤቴ የኅብረት መሥዋዕት7፥14 በተለምዶ የሰላም መሥዋዕት ይባላል። ማቅረብ ነበረብኝ፤

ዛሬ ስእለቴን ፈጸምሁ፤

15ስለዚህ አንተን ለማግኘት ወጣሁ፤

ፈልጌህ ነበር፤ ይኸው አገኘሁህ።

16ዐልጋዬን ከግብፅ የመጣ፣

ጌጠኛ በፍታ አልብሼዋለሁ።

17ዐልጋዬን፣

የከርቤ፣ የዓልሙንና የቀረፋ ሽቱ አርከፍክፌበታለሁ።

18ና፤ እስኪነጋ በጥልቅ ፍቅር እንርካ፤

በፍቅር ራሳችንን እናስደስት።

19ባሌ እቤት የለም፤

ሩቅ አገር ሄዷል።

20በገንዘብ የተሞላ ቦርሳ ወስዷል፤

ጨረቃዋ ሙሉ እስክትሆን አይመለስም።”

21በሚያግባቡ ቃላት አሳተችው፤

በለሰለሰ አንደበቷ አታለለችው።

22ለዕርድ እንደሚነዳ በሬ፣

ወደ ወጥመድ7፥22 የሱርሰት (የሰብዓ ሊቃናትም) ትርጕም እና ዕብራይስጡ ተላላ ይላሉ። እንደሚገባ አጋዘን፣7፥22 የዚህ ስንኝ የዕብራይስጡ ትርጓሜ በርግጠኝነት አይታወቅም።

ሳያንገራግር ተከተላት፤

23ፍላጻ ጕበቱን እስኪወጋው ድረስ፣

ሕይወቱን እንደሚያሳጣው ሳያውቅ፣

በርራ ወደ ወጥመድ እንደምትገባ ወፍ ሆነ።

24ልጆቼ ሆይ፤ አሁንም አድምጡኝ፤

የምለውንም ልብ ብላችሁ ስሙኝ።

25ልባችሁን ወደ መንገዷ አታዘንብሉ፤

ወደ ስሕተት ጐዳናዋም አትግቡ።

26አዋርዳ የጣለቻቸው ብዙ ናቸው፤

የገደለቻቸውም ስፍር ቍጥር የላቸውም።

27ቤቷ ወደ ሲኦል7፥27 ወይም መቃብር የሚወስድ፣

ወደ ሞት ማደሪያም የሚያወርድ ጐዳና ነው።

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Òwe 7:1-27

Ìkìlọ̀ nítorí àwọn aṣẹ́wó

1Ọmọ mi, pa ọ̀rọ̀ mi mọ́,

sì fi àwọn òfin mi pamọ́ sínú ọkàn rẹ.

2Pa òfin mi mọ́, ìwọ yóò sì yè

tọ́jú ẹ̀kọ́ mi bí ẹyinlójú rẹ

3Kọ wọ́n sí ọwọ́ òsì rẹ, má ṣe fi jẹun

kọ wọ́n sí inú wàláà àyà rẹ.

4Wí fún ọgbọ́n pé, “Ìwọ ni arábìnrin mi,”

sì pe òye ní ìbátan rẹ;

5Wọn yóò pa ó mọ́ kúrò lọ́wọ́ obìnrin alágbèrè,

kúrò lọ́wọ́ àjèjì obìnrin àti ọ̀rọ̀ ìtànjẹ rẹ̀.

6Ní ojú fèrèsé ilé è mi

mo wo ìta láti ojú fèrèsé.

7Mo rí i láàrín àwọn aláìmọ̀kan

mo sì kíyèsi láàrín àwọn ọ̀dọ́kùnrin,

ọ̀dọ́ kan tí ó ṣe aláìgbọ́n.

8Ó ń lọ ní pópónà ní tòsí i ilé alágbèrè obìnrin náà,

ó ń rìn lọ sí ọ̀nà ilé e rẹ̀

9Ní ìrọ̀lẹ́ bí oòrùn ṣe ń wọ̀,

bí òkùnkùn ṣe ń bo ni lára.

10Bẹ́ẹ̀ ni obìnrin kan jáde wá láti pàdé rẹ̀,

ó múra bí panṣágà pẹ̀lú ètè búburú.

11(Ó jẹ́ aláriwo àti alágídí,

ìdí rẹ̀ kì í jókòó nílé;

12bí ó ti ń já níhìn-ín ní ó ń já lọ́hùn ún

gbogbo orígun ni ó ti ń ba ní ibùba.)

13Ó dìímú, ó sì fẹnukò ó ní ẹnu

pẹ̀lú ojú díndín ó wí pé:

14“Mo ní ọrẹ àlàáfíà ní ilé;

lónìí ni mo san ẹ̀jẹ́ mi.

15Nítorí náà ni n o ṣe jáde wá pàdé è rẹ;

mo wá ọ káàkiri mo sì ti rí ọ!

16Mo ti tẹ́ ibùsùn mi

pẹ̀lú aṣọ aláràbarà láti ilẹ̀ Ejibiti.

17Mo ti fi nǹkan olóòórùn dídùn sí ibùsùn mi

bí i òjìá, aloe àti kinamoni.

18Wá, jẹ́ kí a lo ìfẹ́ papọ̀ ní kíkún títí di àárọ̀;

jẹ́ kí a gbádùn ara wa pẹ̀lú ìfẹ́!

19Ọkọ ọ̀ mi ò sí nílé;

ó ti lọ sí ìrìnàjò jíjìn.

20Ó mú owó púpọ̀ lọ́wọ́

kò sì ní darí dé kí ó tó di ọ̀sán.”

21Pẹ̀lú ọ̀rọ̀ dídùn ó sì í lọ́nà;

ó tàn án jẹ pẹ̀lú ẹnu dídùn.

22Òun sì tọ̀ ọ́ lọ lẹsẹ̀ kan náà,

bí i màlúù tí ń lọ sí ibùpa,

tàbí bí (aṣiwèrè) àgbọ̀nrín tí ń lọ sí ibi ọgbọ́n ìfabà kọ́.

23Títí tí ọ̀kọ̀ fi gún un ní ẹ̀dọ̀,

bí ẹyẹ ṣe ń fẹ́ wọ inú okùn,

láìmọ̀ pé yóò gba ẹ̀mí òun.

24Nítorí náà báyìí ẹ̀yin ọmọ mi, tẹ́tí sí mi

fọkàn sí nǹkan tí mo sọ.

25Má ṣe jẹ́ kí ọkàn rẹ kí ó yà sí ọ̀nà rẹ̀,

tàbí kí ó rìn lọ sí ipa ọ̀nà rẹ̀.

26Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni àwọn tí ó ti fà lulẹ̀

Ogunlọ́gọ̀ àwọn alágbára ni ó ti pa.

27Ilé e rẹ̀ ni ọ̀nà tààrà sí isà òkú,

tí ó lọ tààrà sí àgbàlá ikú.