ሚክያስ 6 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

ሚክያስ 6:1-16

የእግዚአብሔር ክስ በእስራኤል ላይ

1እግዚአብሔር የሚለውን ስሙ፤

“ተነሡ፤ ጕዳያችሁን በተራሮች ፊት አቅርቡ፤

ኰረብቶች እናንተ የምትሉትን ይስሙ፤

2“ተራሮች ሆይ፤ የእግዚአብሔርን ክስ አድምጡ፤

እናንት የምድር ጽኑ መሠረቶችም፣ ስሙ፤

እግዚአብሔር ከሕዝቡ ጋር ክርክር አለውና፤

ከእስራኤልም ጋር ይፋረዳል።

3“ሕዝቤ ሆይ፤ ምን አድርጌሃለሁ?

ሸክም የሆንሁብህስ እንዴት ነው?

እስቲ መልስልኝ!

4ከግብፅ አወጣሁህ፤

ከባርነት ምድርም ተቤዠሁህ፤

እንዲመሩህ ሙሴን፣

አሮንንና ማርያምን ላክሁልህ።

5ሕዝቤ ሆይ፤

የሞዓብ ንጉሥ ባላቅ የመከረውን፣

የቢዖር ልጅ በለዓም የመለሰለትንም እስቲ አስቡ፤

የእግዚአብሔርን የጽድቅ ሥራ ታውቁ ዘንድ፣

ከሰጢም እስከ ጌልገላ የተጓዛችሁትን ዐስቡ።”

6ምን ይዤ በእግዚአብሔር ፊት ልቅረብ፣

በልዑል አምላክ ፊት ልስገድ?

የሚቃጠለውን መሥዋዕት፣

ከአንድ ዓመት ጥጃ ጋር ይዤ በፊቱ ልቅረብን?

7በአንድ ሺሕ አውራ በጎች፣

በዐሥር ሺሕ የዘይት ፈሳሽ እግዚአብሔር ደስ ይለዋልን?

ስለ በደሌ የበኵር ልጄን፣

ስለ ነፍሴም ኀጢአት የሆዴን ፍሬ ላቅርብለትን?

8ሰው ሆይ፤ መልካም የሆነውን አሳይቶሃል፤

እግዚአብሔር ከአንተ የሚፈልገው ምንድን ነው?

ፍትሕን ታደርግ ዘንድ፣ ምሕረትንም ትወድድ ዘንድ፣

በአምላክህም ፊት በትሕትና ትራመድ ዘንድ አይደለምን?

የእስራኤል በደልና ቅጣት

9ስምህን መፍራት ጥበብ ነው፤

ስሙ! እግዚአብሔር ከተማዪቱን እንዲህ እያለ ይጣራል፤

“በትሩን አስቡ፤ ያዘጋጀውም ማን እንደ ሆነ አስታውሱ6፥9 የዚህ ስንኝ የዕብራይስጡ ትርጕም በርግጠኝነት አይታወቅም።

10የክፋት ቤት ሆይ፤

በግፍ የተገኘ ሀብታችሁን፣

በሐሰተኛ መስፈሪያ የሰበሰባችሁትን አስጸያፊ ነገር እረሳዋለሁን?

11አባይ ሚዛን የያዘውን ሰው፣

ሐሰተኛ መመዘኛ በከረጢት የቋጠረውን ንጹሕ ላድርገውን?

12ባለጠጎቿ ግፈኞች፣

ሰዎቿ ሐሰተኞች ናቸው፤

ምላሳቸውም አታላይ ናት።

13ስለዚህ አንተን አጠፋሃለሁ፣

ከኀጢአትህ የተነሣ አፈራርስሃለሁ።

14ትበላለህ፤ ነገር ግን አትጠግብም፤

ሆድህ እንዳለ ባዶውን6፥14 የዚህ ቃል የዕብራይስጡ ትርጕም በርግጠኝነት አይታወቅም። ይቀራል፤

ታከማቻለህ፤ ነገር ግን አይጠራቀምልህም፤

የሰበሰብኸውን ለሰይፍ አደርገዋለሁና።

15ትዘራለህ፤ ነገር ግን አታጭድም፤

የወይራ ዘይት ትጨምቃለህ፤ ነገር ግን ዘይቱን አትቀባም፤

ወይንን ትቈርጣለህ፤ ነገር ግን የወይን ጠጅ አትጠጣም።

16የዖምሪን ሥርዐት፣

የአክዓብን ቤት ልምድ ሁሉ የሙጥኝ ብለሃል፤

ትውፊታቸውንም ተከትለሃል።

ስለዚህ አንተን ለውድመት፣

ሕዝብህን ለመዘባበቻ አሳልፌ እሰጣለሁ፤

አሕዛብም ይሣለቁብሃል6፥16 የሰብዓ ሊቃናት ትርጕም ከዚህ ጋር ሲስማማ የዕብራይስጡ ግን የሕዝቤን ስድብ ትሸከማለህ ይላል።።”

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Mika 6:1-16

Ọlọ́run pe Israẹli níjà

1Ẹ fi etí sí ohun tí Olúwa wí:

“Dìde dúró, bẹ ẹ̀bẹ̀ fún ẹjọ́ rẹ níwájú òkè ńlá;

sì jẹ́ kí àwọn òkè kéékèèkéé gbọ́ ohun tí ó fẹ́ wí.

2“Gbọ́, ìwọ òkè ńlá, ẹ̀sùn Olúwa;

gbọ́, ìwọ ìpìlẹ̀ ilé ayérayé.

Nítorí Olúwa ń bá àwọn ènìyàn rẹ̀ wíjọ́;

òun yóò sì bá Israẹli rojọ́.

3“Ẹ̀yin ènìyàn mi, kí ni mo ṣe fún yín?

Àti nínú kí ni mo ti dá yin lágara? Dá mi lóhùn.

4Nítorí èmi mú un yín gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti wá,

mo sì rà yín padà láti ilẹ̀ ẹrú wá.

Mo rán Mose láti darí yín,

bákan náà mo rán Aaroni àti Miriamu síwájú rẹ̀.

5Ìwọ ènìyàn mi,

rántí ohun tí Balaki ọba Moabu gbèrò

àti ohun tí Balaamu ọmọ Beori dáhùn.

Rántí ìrìnàjò rẹ̀ láti Ṣittimu dé Gilgali,

kí ìwọ ba le mọ òdodo Olúwa.”

6Kí ni èmi yóò ha mú wá síwájú Olúwa

tí èmi ó fi tẹ ara mi ba níwájú Ọlọ́run gíga?

Kí èmi ha wá sí iwájú rẹ̀ pẹ̀lú ọrẹ ẹbọ sísun,

pẹ̀lú ọmọ màlúù ọlọ́dún kan?

7Ǹjẹ́ Olúwa yóò ní inú dídùn sí ẹgbẹgbàarùn-ún àgbò,

tàbí sí ẹgbẹgbàarùn-ún ìṣàn òróró?

Èmi yóò ha fi àkọ́bí mi sílẹ̀ fún ìré-òfin-kọjá mi,

èso inú ara mi fún ẹ̀ṣẹ̀ ọkàn mi?

8Ó ti fihàn ọ́, ìwọ ènìyàn, ohun tí ó dára,

àti ohun tí Olúwa ń béèrè lọ́wọ́ rẹ?

Bí kò ṣe láti ṣe òtítọ́, kí o sì fẹ́ràn àánú,

àti kí o rìn ní ìrẹ̀lẹ̀ pẹ̀lú Ọlọ́run rẹ̀.

Ẹ̀ṣẹ̀ Israẹli àti ìjìyà wọn

9Gbọ́! Ohùn Olúwa kígbe sí ìlú ńlá náà,

láti jẹ ọlọ́gbọ́n ni láti bẹ̀rù orúkọ rẹ.

“Ẹ kíyèsi ọ̀pá rẹ̀ gbọ́ ọ̀pá àti Ẹni náà tí ó yàn án

10Ǹjẹ́ ìṣúra ìwà búburú ha wà

ní ilé ènìyàn búburú síbẹ̀,

àti òṣùwọ̀n àìkún tí ó jẹ́ ohun ìbínú?

11Ǹjẹ́ èmi ha lè kà wọ́n sí mímọ́

pẹ̀lú òṣùwọ̀n búburú,

pẹ̀lú àpò òṣùwọ̀n ẹ̀tàn?

12Àwọn ọlọ́rọ̀ inú rẹ̀ kún fún ìwà ipá;

àwọn tí ń gbé inú rẹ̀ ti ọ̀rọ̀ èké

àti ahọ́n wọn ń sọ ẹ̀tàn?

13Nítorí náà ni èmi yóò ṣe mú ọ ṣàìsàn ní lílù ọ́,

láti sọ ọ́ dahoro nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ.

14Ìwọ yóò jẹun ṣùgbọ́n kì yóò yó;

ìyàn yóò wà láàrín rẹ;

Ìwọ yóò kó pamọ́, ṣùgbọ́n ìwọ kì yóò lò láìléwu,

nítorí ohun tí ìwọ kò pamọ́ ni èmi yóò fi fún idà.

15Ìwọ yóò gbìn ṣùgbọ́n ìwọ kì yóò kórè

ìwọ yóò tẹ olifi,

ṣùgbọ́n ìwọ kì yóò fi òróró rẹ̀ kún ara rẹ;

ìwọ yóò tẹ èso àjàrà, ṣùgbọ́n ìwọ kì yóò mu wáìnì.

16Nítorí tí ìwọ ti pa òfin Omri mọ́,

àti gbogbo iṣẹ́ ilé Ahabu,

tí ó sì ti tẹ̀lé ìmọ̀ràn wọn,

nítorí náà ni èmi yóò ṣe mú ọ fún ìparun

àti àwọn ènìyàn rẹ fún ìfiṣe ẹlẹ́yà;

ìwọ yóò sì ru ẹ̀gàn àwọn ènìyàn mi.”