መዝሙር 77 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

መዝሙር 77:1-20

መዝሙር 77

የእስራኤል ጥንተ ነገር አሰላስሎ

ለመዘምራን አለቃ፤ ለኤዶታም፤ የአሳፍ መዝሙር።

1ድምፄን ከፍ አድርጌ ወደ እግዚአብሔር ጮኽሁ፤

ይሰማኝም ዘንድ ወደ አምላክ ጮኽሁ።

2በመከራዬ ቀን እግዚአብሔርን ፈለግሁት፤

በሌሊትም ያለ ድካም እጆቼን ዘረጋሁ፤

ነፍሴም አልጽናና አለች።

3አምላክ ሆይ፤ አንተን ባሰብሁ ቍጥር ቃተትሁ፤

ባወጣሁ ባወረድሁም መጠን መንፈሴ ዛለች። ሴላ

4ዐይኖቼ እንዳይከደኑ ያዝሃቸው፤

መናገር እስኪሳነኝ ድረስ ታወክሁ።

5የድሮውን ዘመን አሰብሁ፤

የጥንቶቹን ዓመታት አውጠነጠንሁ።

6ዝማሬዬን በሌሊት አስታወስሁ፤

ከልቤም ጋር ተጫወትሁ፤ መንፈሴም ተነቃቅቶ እንዲህ ሲል ጠየቀ፦

7“ለመሆኑ፣ ጌታ ለዘላለም ይጥላልን?

ከእንግዲህስ ከቶ በጎነትን አያሳይምን?

8ምሕረቱስ ለዘላለም ጠፋን?

የገባውስ ቃል እስከ ወዲያኛው ተሻረን?

9እግዚአብሔር ቸርነቱን ዘነጋ?

ወይስ ከቍጣው የተነሣ ርኅራኄውን ነፈገ?” ሴላ

10እኔም፣ “የልዑል ቀኝ እጅ እንደ ተለወጠ ማሰቤ፣

ይህ ድካሜ ነው” አልሁ።

11የእግዚአብሔርን ሥራ አስታውሳለሁ፤

የጥንት ታምራትህን በርግጥ አስታውሳለሁ፤

12ሥራህን ሁሉ አሰላስላለሁ፤

ድንቅ ሥራህን ሁሉ አውጠነጥናለሁ።

13አምላክ ሆይ፤ መንገድህ ቅዱስ ነው፤

እንደ አምላካችን ያለ ታላቅ አምላክ ማን ነው?

14ታምራትን የምታደርግ አምላክ አንተ ነህ፤

በሕዝቦችም መካከል ኀይልህን ትገልጣለህ።

15የያዕቆብንና የዮሴፍን ልጆች፣

ሕዝብህን በክንድህ ተቤዠሃቸው። ሴላ

16አምላክ ሆይ፤ ውሆች አዩህ፤

ውሆች አንተን አይተው ተሸማቀቁ፤

ጥልቆችም ተነዋወጡ።

17ደመናት ውሃን አንጠባጠቡ፤

ሰማያት አንጐደጐዱ፤

ፍላጾችህም ዙሪያውን አብለጨለጩ።

18የነጐድጓድህ ድምፅ በዐውሎ ነፋስ ውስጥ ተሰማ፤

መብረቅህ ዓለምን አበራው፤

ምድርም ራደች፤ ተንቀጠቀጠች።

19መንገድህ በባሕር ውስጥ ነው፤

መሄጃህም በታላቅ ውሃ ውስጥ ነው፤

ዱካህ ግን አልታወቀም።

20በሙሴና በአሮን እጅ፣

ሕዝብህን እንደ በግ መንጋ መራኸው።

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 77:1-20

Saamu 77

Fún adarí orin. Fún Jedutuni. Ti Asafu. Saamu.

1Mó kígbe sí Ọlọ́run fún ìrànlọ́wọ́;

mo kígbe sí Ọlọ́run láti gbọ́ tèmi.

2Nígbà tí mo wà nínú ìpọ́njú,

mo wá Olúwa;

ní òru ni mo na ọwọ́ mi jáde ní àìkáárẹ̀

ọkàn mí sì kọ̀ láti tù ú nínú.

3Èmi rántí rẹ, Ọlọ́run,

mo sì kẹ́dùn;

mo ṣe àròyé, ẹ̀mí mi sì rẹ̀wẹ̀sì. Sela.

4Ìwọ kò fẹ́ kí èmi fi ojú ba oorun,

mo dààmú tó bẹ́ẹ̀ tí ń kò le sọ̀rọ̀.

5Mo ronú nípa ọjọ́ ìgbàanì;

ọdún pípẹ́ sẹ́yìn;

6Mo rántí orin mi ní òru.

Èmi ń bá àyà mi sọ̀rọ̀,

ọkàn mi sì ń ṣe àwárí jọjọ.

7“Olúwa yóò ha kọ̀ títí láé?

Ki yóò ha ṣe ojúrere rẹ̀ mọ́?

8Ṣe ìfẹ́ rẹ̀ àti àánú rẹ̀ ti kú lọ láéláé?

Ìlérí rẹ̀ ha kùnà títí ayé?

9Ọlọ́run ha gbàgbé láti máa ṣàánú?

Ní ìbínú rẹ̀, ó ha sé ojúrere rẹ̀ mọ́?” Sela.

10Èmi wí pé, “Èyí ní ẹ̀dùn ọkàn mi,

pé ọwọ́ ọ̀tún Ọ̀gá-ògo jùlọ ti yípadà”.

11Èmi ó rántí iṣẹ́ Olúwa:

bẹ́ẹ̀ ni, èmi ó rántí iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ ọjọ́ pípẹ́.

12Èmi ṣàṣàrò lórí iṣẹ́ rẹ gbogbo

pẹ̀lú, ènìyàn sì máa sọ̀rọ̀ gbogbo iṣẹ́ agbára rẹ.

13Ọlọ́run, Ọ̀nà rẹ jẹ́ mímọ́.

Ọlọ́run wo ni ó sì tóbi bí Ọlọ́run wa?

14Ìwọ ni Ọlọ́run tó ń ṣe ìyanu;

ìwọ fi agbára rẹ hàn nínú àwọn ènìyàn.

15Pẹ̀lú ọwọ́ agbára rẹ ni ìwọ ra àwọn ènìyàn padà,

àwọn ọmọ Jakọbu àti Josẹfu. Sela.

16Nígbà tí àwọn omi rí Ọlọ́run,

nígbà tí àwọn omi rí ọ,

ẹ̀rù bà wọ́n,

nítòótọ́ ara ibú kò balẹ̀.

17Àwọn ojú ọ̀run tú omi sílẹ̀,

àwọsánmọ̀ fi àrá dáhùn;

ọfà rẹ̀ ń tàn sẹ́yìn àti síwájú

18Àrá rẹ̀ ni a gbọ́ nínú ìjì,

ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ mọ́lẹ̀ sí gbogbo ayé;

ayé bẹ̀rù, wọ́n sì wárìrì.

19Ipa rẹ̀ gba Òkun, ọ̀nà rẹ̀ ń bẹ nínú Òkun,

Ọ̀nà la omi alágbára kọjá ipa rẹ̀ ń bẹ nínú líla omi alágbára kọjá,

nítòótọ́ a kò rí ojú ẹsẹ̀ rẹ̀.

20Ó tọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọ̀wọ́ ẹran

nípa ọwọ́ Mose àti Aaroni.