መዝሙር 146 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

መዝሙር 146:1-10

መዝሙር 146

ለረድኤት አምላክ ምስጋና

1ሃሌ ሉያ።146፥1 አንዳንዶች ከቍጥር 10 ጭምር እግዚአብሔር ይመስገን ይላሉ።

ነፍሴ ሆይ፤ እግዚአብሔርን ባርኪ።

2በምኖርበት ዘመን ሁሉ እግዚአብሔርን

አመሰግናለሁ፤

በሕይወትም እስካለሁ ለአምላኬ እዘምራለሁ።

3በገዦች አትታመኑ፤ ማዳን በማይችሉ ሥጋ ለባሾችም አትመኩ።

4መንፈሳቸው ትወጣለች፤ ወደ መሬታቸውም ይመለሳሉ፤

ያን ጊዜም ዕቅዳቸው እንዳልነበር ይሆናል።

5ረዳቱ የያዕቆብ አምላክ የሆነ፣

ተስፋውንም በአምላኩ በእግዚአብሔር ላይ የጣለ ሰው ምስጉን ነው፤

6እርሱ ሰማይንና ምድርን፣ ባሕርንም፣

በእነዚህም ውስጥ ያለውን ሁሉ የፈጠረ፣

ታማኝነቱንም ለዘላለም የሚጠብቅ ነው፤

7ለተበደሉት የሚፈርድ፣

ለተራቡት ምግብን የሚሰጥ እርሱ ነው፤

እግዚአብሔር እስረኞችን ከእስራት ያወጣል፤

8እግዚአብሔር የዕውራንን ዐይን ያበራል፤

እግዚአብሔር የተዋረዱትን ከፍ ያደርጋል፤

እግዚአብሔር ጻድቃንን ይወድዳል፤

9እግዚአብሔር ስደተኞችን ይጠብቃል፤

ድኻ ዐደጎችንና መበለቶችን ይደግፋል፤

የክፉዎችን መንገድ ግን ያጠፋል።

10እግዚአብሔር ለዘላለም ይነግሣል፤

ጽዮን ሆይ፤ አምላክሽ ለትውልድ ሁሉ ንጉሥ ነው።

ሃሌ ሉያ።

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 146:1-10

Saamu 146

1Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.

Fi ìyìn fún Olúwa, ìwọ ọkàn mi.

2Èmi yóò yin Olúwa ní gbogbo ayé mi;

Èmi yóò kọrin ìyìn sí Ọlọ́run, níwọ̀n ìgbà tí mo bá wà láààyè.

3Ẹ má ṣe ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú àwọn ọmọ-aládé,

àní, ọmọ ènìyàn,

lọ́wọ́ ẹni tí kò sí ìrànlọ́wọ́.

4Ẹ̀mí rẹ jáde lọ, ó padà sí erùpẹ̀:

Ní ọjọ́ náà gan, èrò wọn yóò di òfo:

5Ìbùkún ni fún ẹni tí

Ọlọ́run Jakọbu ń ṣe ìrànlọ́wọ́ rẹ̀

tí ìrètí rẹ̀ wà nínú Olúwa Ọlọ́run rẹ̀.

6Ẹni tí ó dá ọ̀run àti ayé,

òkun àti ohun gbogbo tí ń bẹ nínú wọn,

ẹni tí ó pa òtítọ́ mọ́ títí ayé.

7Ẹni tí ń ṣe ìdájọ́ àwọn tí a ni lára

tí ó fi oúnjẹ fún àwọn tí ebi ń pa

Olúwa, tú àwọn oǹdè sílẹ̀ (ẹlẹ́wọ̀n)

8Olúwa mú àwọn afọ́jú ríran,

Olúwa, gbé àwọn tí a rẹ̀ sílẹ̀ ga,

Olúwa fẹ́ràn àwọn olódodo.

9Olúwa ń dá ààbò bo àwọn àlejò

ó sì ń dá àwọn aláìní baba àti opó sí

ṣùgbọ́n ó ba ọ̀nà àwọn ènìyàn búburú jẹ́.

10Olúwa jẹ ọba títí láé;

Ọlọ́run rẹ, ìwọ Sioni, àti fún gbogbo ìran.

Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.