መዝሙር 132 – NASV & YCB

New Amharic Standard Version

መዝሙር 132:1-18

መዝሙር 132

የክብረ በዓል መዝሙር

132፥8-10 ተጓ ምብ – 2ዜና 6፥41-42

መዝሙረ መዓርግ።

1እግዚአብሔር ሆይ፤ ዳዊትን፣

የታገሠውንም መከራ ሁሉ ዐስብ፤

2እርሱ ለእግዚአብሔር ማለ፤

ለያዕቆብም ኀያል አምላክ እንዲህ ሲል ተሳለ፤

3“ወደ ቤቴ አልገባም፤

ዐልጋዬም ላይ አልወጣም፤

4ለዐይኖቼ እንቅልፍን፣

ለሽፋሽፍቶቼም ሸለብታ አልሰጥም፤

5ለእግዚአብሔር ስፍራን፣

ለያዕቆብም ኀያል አምላክ ማደሪያን እስካገኝ ድረስ።”

6እነሆ፤ በኤፍራታ ሰማነው፤

በቂርያትይዓሪም132፥6 አንዳንዶቹ ያዓር ይላሉ። አገኘነው።

7“ወደ ማደሪያው እንግባ፤

እግሮቹ በሚቆሙበት ቦታ እንስገድ።

8እግዚአብሔር ሆይ፤ ተነሥ፤

አንተና የኀይልህ ታቦት ወደ ማረፊያህ ስፍራ ሂዱ።

9ካህናትህ ጽድቅን ይልበሱ፤

ቅዱሳንህም እልል ይበሉ።”

10ስለ አገልጋይህ ስለ ዳዊት ስትል፣

የቀባኸውን ሰው አትተወው።

11እግዚአብሔር ለዳዊት በእውነት ማለ፤

በማይታጠፍም ቃሉ እንዲህ አለ፤

“ከገዛ ራስህ ፍሬ፣

በዙፋንህ ላይ አስቀምጣለሁ።

12ወንዶች ልጆችህ ኪዳኔን፣

የማስተምራቸውንም ምስክርነቴን ቢጠብቁ፣

ልጆቻቸው በዙፋንህ ላይ፣

ለዘላለም ይቀመጣሉ።”

13እግዚአብሔር ጽዮንን መርጧታልና፣

ማደሪያውም ትሆን ዘንድ ወድዷልና እንዲህ አለ፤

14“ይህች ለዘላለም ማረፊያዬ ናት፤

ፈልጌአታለሁና በእርሷ እኖራለሁ።

15እጅግ አትረፍርፌ እባርካታለሁ፤

ድኾቿን እንጀራ አጠግባለሁ።

16ለካህናቷ ድነትን አለብሳለሁ፤

ቅዱሳኗም በደስታ ይዘምራሉ።

17“በዚህም ለዳዊት ቀንድ132፥17 እዚህ ላይ ቀንድ የጥንካሬ ትእምርት ሲሆን፣ ንጉሥን ያመለክታል። አበቅላለሁ፤

ለቀባሁትም ሰው መብራት አዘጋጃለሁ።

18ጠላቶቹን ኀፍረት አከናንባቸዋለሁ፤

እርሱ ግን በራሱ ላይ የደፋው ዘውድ ያበራል።”

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 132:1-18

Saamu 132

Orin fún ìgòkè.

1Olúwa, rántí Dafidi

nínú gbogbo ìpọ́njú rẹ̀.

2Ẹni tí ó ti búra fún Olúwa,

tí ó sì ṣe ìlérí fún Alágbára Jakọbu pé.

3Nítòótọ́, èmi kì yóò wọ inú àgọ́ ilé mi lọ,

bẹ́ẹ̀ èmi kì yóò gun orí àkéte mi:

4Èmi kì yóò fi oorun fún ojú mi,

tàbí òògbé fún ìpéǹpéjú mi,

5Títí èmi ó fi rí ibi fún Olúwa,

ibùjókòó fún Alágbára Jakọbu.

6Kíyèsi i, àwa gbúròó rẹ̀ ni Efrata:

àwa rí i nínú oko ẹgàn náà.

7Àwa ó lọ sínú àgọ́ rẹ̀:

àwa ó máa sìn níbi àpótí ìtìsẹ̀ rẹ̀

8Olúwa, dìde sí ibi ìsinmi rẹ:

ìwọ, àti àpótí agbára rẹ.

9Kí a fi òdodo wọ àwọn àlùfáà rẹ:

kí àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ kí ó máa hó fún ayọ̀.

10Nítorí tí Dafidi ìránṣẹ́ rẹ̀

Má ṣe yí ojú ẹni òróró rẹ padà.

11132.11: Sm 89.3-4; Ap 2.30.Olúwa ti búra nítòótọ́ fún Dafidi:

Òun kì yóò yípadà kúrò nínú rẹ̀,

nínú irú-ọmọ inú rẹ ni èmi ó gbé kalẹ̀ sí orí ìtẹ́ rẹ.

12Bí àwọn ọmọ rẹ̀ yóò bá pa májẹ̀mú mi mọ́

àti ẹ̀rí mi tí èmi yóò kọ́ wọn,

àwọn ọmọ wọn pẹ̀lú yóò jókòó lórí ìtẹ́ rẹ láéláé.

13Nítorí tí Olúwa ti yan Sioni:

ó ti fẹ́ ẹ fún ibùjókòó rẹ̀.

14Èyí ni ibi ìsinmi mi láéláé:

níhìn-ín ni èmi yóò máa gbé:

nítorí tí mo fẹ́ ẹ.

15Èmi yóò bùkún oúnjẹ rẹ̀ púpọ̀púpọ̀:

èmi yóò fi oúnjẹ tẹ́ àwọn tálákà rẹ̀ lọ́rùn.

16Èmi yóò sì fi ìgbàlà wọ àwọn àlùfáà rẹ̀:

àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ yóò máa hó fún ayọ̀.

17Níbẹ̀ ni èmi yóò gbé mú ìwo Dafidi yọ̀,

èmi ti ṣe ìlànà fìtílà kan fún ẹni òróró mi.

18Àwọn ọ̀tá rẹ̀ ni èmi yóò fi ìtìjú wọ̀:

ṣùgbọ́n lára òun tìkára rẹ̀ ni adé yóò máa gbilẹ̀.