詩篇 7 – JCB & YCB

Japanese Contemporary Bible

詩篇 7:1-17

7

1私の神、主よ。

頼れるのは、ただあなただけです。

どうか、迫害する者からお救いください。

2だれも助ける者がいないために、

彼らがライオンのように襲いかかり、

私をさらって行くことがありませんように。

3主よ。

もし、私が悪事を働いているのなら、

4悪をもって善に報い、

えり好みして人を不当に攻撃しているというのなら、

5もしそうであれば、敵が私を滅ぼし、押しつぶし、

ちりの中でこのいのちを踏みにじることを

神がお許しになったとしても、

私は何も言えません。

6しかし、主よ。

怒り狂う敵に対しては、

どうぞ怒りをもって立ち上がってください。

目を覚ましてください。

どうか、正しいさばきを行ってください、主よ。

7-8異邦の民を召集し、高い座から

彼らの罪をさばいてください。

そして、私の潔白を明らかにしてください。

全員の前で、私の名誉を回復し、

誠実を証明してください。

9ああ主よ、すべての悪を根絶やしにし、

心の底から主を礼拝する者を祝福してください。

正しい神である主は、人の心の奥底まで見抜き、

いっさいの動機と思いとをお調べになります。

10神は私の盾。

私を守ってくださるお方です。

神は、真実で正しい人を救われます。

11神は公平な裁判官。

日々、悪者には怒りを燃やします。

12悔い改めない者を

研ぎすました剣で殺します。

神は弓を引きしぼり、

13恐ろしい火の矢をつがえています。

14悪者は良くないことを考え、

陰謀を企てては、偽りと背信に走ります。

15そのような者たちは、

自らしかけた罠に落ち込みます。

16他人にふるった暴力がわが身に跳ね返り、

いのちを奪われるといいのに。

17ああ、どれほど主に感謝していることでしょう。

その恵みは測り知れません。

王の王なる主の御名を、力の限りほめ歌います。

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 7:1-17

Saamu 7

Ṣiggaioni ti Dafidi, èyí tí ó kọ sí Olúwa nípa Kuṣi, ará Benjamini.

1Olúwa Ọlọ́run mi, ààbò mi wà nínú rẹ;

gba mí là kí o sì tú mi sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn tó ń lé mi,

2kí wọn ó má ba à fa ọkàn mi ya gẹ́gẹ́ bí kìnnìún,

wọ́n á ya á pẹ́rẹpẹ̀rẹ láìsí ẹni tí yóò gbà mí.

3Olúwa Ọlọ́run mi, tí èmi bá ṣe èyí

tí ẹ̀bi sì wà ní ọwọ́ mi

4Bí èmi bá ṣe ibi sí ẹni tí ń wá àlàáfíà pẹ̀lú mi,

tí mo ja ọ̀tá mi lólè láìnídìí:

5Nígbà náà, jẹ́ kí ọ̀tá mi lé mi kí wọn sì mú mi;

jẹ́ kí òun kí ó tẹ ọkàn mi mọ́lẹ̀

kí wọn sì mú mi sùn nínú eruku. Sela.

6Dìde, Olúwa, nínú ìbínú rẹ;

dìde lòdì sí ìrunú àwọn ọ̀tá mi.

Jí, Ọlọ́run mi; kéde òdodo.

7Kí ìpéjọ àwọn ènìyàn yíká.

Jọba lórí wọn láti òkè wá;

8Jẹ́ kí Olúwa ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn.

Ṣe ìdájọ́ mi, Olúwa, gẹ́gẹ́ bí òdodo mi,

gẹ́gẹ́ bí ìwà òtítọ́, ẹni gíga jùlọ.

97.9: If 2.23.Ọlọ́run Olódodo,

Ẹni tí ó ń wo inú àti ọkàn,

tí ó ń mú òpin sí ìwà ipá ẹni búburú

tí ó sì ń pa àwọn olódodo mọ́.

10Ààbò mi ń bẹ lọ́dọ̀ Ọlọ́run,

ẹni tí ń ṣe ìgbàlà òtítọ́ ní àyà.

11Ọlọ́run ni onídàájọ́ òtítọ́,

Ọlọ́run tí ń sọ ìrunú rẹ̀ ní gbogbo ọjọ́.

12Bí kò bá yípadà,

Òun yóò pọ́n idà rẹ̀ mú;

ó ti fa ọrun rẹ̀ le ná, ó ti múra rẹ̀ sílẹ̀.

13Ó ti pèsè ohun ìjà ikú sílẹ̀;

ó ti pèsè ọfà iná sílẹ̀.

14Ẹni tí ó lóyún ohun búburú,

tí ó sì lóyún wàhálà, ó bí èké jáde.

15Ẹni tí ó gbẹ́ ọ̀fìn, tí ó kó o jáde

jì sí kòtò tí ó gbẹ́ sílẹ̀.

16Wàhálà tí ó fà padà sórí rẹ̀;

Ìwà ipá rẹ̀ padà sórí ara rẹ̀.

17Èmi ó fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí òdodo rẹ̀,

Èmi ó kọrin ìyìn sí Olúwa Ọ̀gá-ògo jùlọ.