ホセア書 12 – JCB & YCB

Japanese Contemporary Bible

ホセア書 12:1-14

12

1イスラエルは風を追い、

つむじ風の番をしています。

全く危険な遊びです。

エジプトやアッシリヤに贈り物をし、援助を求めますが、そのお返しは価値のない約束です。

2けれども、主はユダを告訴しようとしています。

ヤコブはその行いのゆえに、公正に罰せられます。

3ヤコブは生まれる時に兄弟と争い、

大人になってからは神とさえ戦ったのです。

4まさに、御使いと格闘して勝ちました。

彼は御使いに、祝福してくれるようにと

泣いて頼みました。

ベテルでは、

神と顔と顔を合わせるようにして出会い、

神は彼に語りかけました。

5まことに、主は天の軍勢の神であり、

主と呼ばれるにふさわしい方です。

6さあ、神に立ち返り、

愛と公正の原理に立ちなさい。

いつも、あなたの神に期待しなさい。

7ところが私の同胞は、不正なはかりで物を売る、

ずる賢い商人のようです。

だますことが好きなのです。

8エフライムは自慢しています。

「私はこんなに金持ちになった。

すべて自分でもうけたのだ。」

しかし、富に罪を償うことはできません。

9「わたしは、あなたをエジプトの奴隷生活から

救い出した主、同じ神だ。

わたしは、毎年の仮庵の祭りの時のように、

あなたを再び天幕(テント)に住まわせる。

10わたしは預言者を遣わし、

多くの幻やたとえや夢で警告した。」

11それなのに、ギルガルの罪は相も変わらず、

公然と行われています。

畑のうねのように何列も祭壇が築かれ、

偶像へのいけにえのために使われています。

ギルアデも、偶像を拝む愚か者であふれています。

12ヤコブはアラム(シリヤ)へ逃げ、

羊の番をして妻をめとりました。

13それから主はその民をエジプトから連れ出すために

一人の預言者を立て、

彼らを導き、守るようにさせました。

14それなのに、エフライムは主をひどく怒らせました。

その罪の支払いとして、主は死の宣告を下すのです。

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Hosea 12:1-14

1Efraimu ń jẹ afẹ́fẹ́;

o ń lépa afẹ́fẹ́ ìwọ̀-oòrùn ní gbogbo ọjọ́.

O sì ń gbèrú nínú irọ́

o dá májẹ̀mú pẹ̀lú Asiria

o sì fi òróró olifi ránṣẹ́ sí Ejibiti.

2Olúwa ní ẹjọ́ kan tí yóò bá Juda rò,

yóò fì ìyà jẹ Jakọbu gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ̀

yóò sì sán fún un gẹ́gẹ́ bí i ìṣe rẹ̀.

3Láti inú oyún ni ó ti di arákùnrin rẹ̀ mú ni gìgísẹ̀,

àti nípa ipá rẹ̀ ó ni agbára pẹ̀lú Ọlọ́run

4Ó bá angẹli ja ìjàkadì, ó sì borí rẹ̀

o sọkún, ó sì bẹ̀bẹ̀ fún ojúrere rẹ̀

Ó bá Olúwa ní Beteli

Ó sì bá a sọ̀rọ̀ níbẹ̀,

5àní Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun;

Olúwa ni orúkọ ìrántí rẹ̀

6Ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ padà sọ́dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀;

di ìfẹ́ àti ìdájọ́ òdodo mú

kí ẹ sì dúró de Ọlọ́run yín nígbà gbogbo.

7Oníṣòwò ń lo òṣùwọ̀n èké

o fẹ́ràn láti rẹ́ ni jẹ.

812.8: If 3.17.Efraimu gbéraga,

“Èmi ní ìní fún ara mi, mo sì ti di ọlọ́rọ̀,

pẹ̀lú gbogbo ọrọ̀ mi yìí, wọn kò le ká àìṣedéédéé

tàbí ẹ̀ṣẹ̀ kankan mọ́ mi lọ́wọ́.”

9“Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ;

ẹni tí ó mu ọ jáde wá láti ilẹ̀ Ejibiti;

èmi yóò tún mú yín gbé nínú àgọ́

bí i ọjọ́ àjọ̀dún tí a yàn wọ̀n-ọn-nì

10Mo sọ fún àwọn wòlíì,

mo fi ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìran hàn wọ́n

mo sì pa òwe láti ẹnu wòlíì wọn.”

11Gileadi ha burú bí?

Àwọn ènìyàn rẹ̀ jẹ́ asán.

Ǹjẹ́ wọ́n ń fi akọ màlúù rú ẹbọ ní Gilgali?

Gbogbo pẹpẹ wọ́n sì dàbí ebè

nínú aporo oko.

12Jakọbu sálọ si orílẹ̀-èdè Aramu;

Israẹli sìn kí o tó fẹ́ ìyàwó

ó ṣe ìtọ́jú ẹran láti fi san owó ìyàwó.

13Olúwa lo wòlíì kan láti mú Israẹli jáde wá láti Ejibiti,

nípasẹ̀ wòlíì kan ó ṣe ìtọ́jú rẹ̀.

14Ṣùgbọ́n Efraimu ti mú un bínú gidigidi;

Olúwa rẹ̀ yóò sì fi ẹ̀bi ìtàjẹ̀ sílẹ̀ sí orí rẹ̀

òun yóò sì san án padà fún un nítorí ìwà ẹ̀gàn an rẹ̀.