エゼキエル書 19 – JCB & YCB

Japanese Contemporary Bible

エゼキエル書 19:1-14

19

指導者たちへの哀歌

1イスラエルの指導者たちのために哀歌を歌いなさい。

2あなたの母はなんという女だろう。

まるで雌のライオンのようで、

子どももライオンの子のようだ。

3そのうちの一頭(エホアハズ王)は

強いライオンに育ち、獲物を捕らえることを習い、

ついに人を食べるようになった。

4そこで、諸国から狩人が集められ、

そのライオンを落とし穴で捕らえると、

鎖につないでエジプトへ連れて行った。

5母ライオンであるイスラエルは、

その子への望みが絶たれたので、

残る子の中から別の一頭(エホヤキン王)を取り、

百獣の王となるように訓練した。

6それで、このライオンは仲間の指導者となり、

獲物を捕らえることを習い、

やがて人を食べるようになった。

7近隣の国々の宮殿を破壊し、町々を廃墟とし、

農地を荒らし回り、作物をだめにした。

この地の人はみな、そのうなり声を聞くと、

恐ろしさのあまり震え上がった。

8それで、諸国の軍が四方から攻め上り、

彼を落とし穴に追い込んで捕らえた。

9そして彼を檻に入れ、バビロン王の前に連れて行った。

彼は捕囚となり、その声は二度と

イスラエルの山々で聞かれなくなった。

10あなたの母はまた、

水のほとりに植えられた

ぶどうの木のようだった。

豊かな水のおかげで葉も青々と茂っていた。

11その一番強い枝が王の杖となった。

それは他のものから抜きんでて高く、

遠くからもすぐ目についた。

12だが、そのぶどうの木も憤りで根こそぎ引き抜かれ、

地に投げ捨てられた。

枝は強い東風に折られて枯れ、実も焼かれてしまった。

13今ぶどうの木は、

水のない乾ききった荒野に植えられている。

14すでに内側から枯れ始め、

強そうな枝ぶりも見られない。

この悲しい預言は、すでに現実となっている。

もう、その実現をとどめることはできない。」

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Esekiẹli 19:1-14

Orin ọfọ̀ nítorí àwọn ọmọ-aládé Israẹli

1“Kọ orin ọ̀fọ̀ nítorí àwọn ọmọ-aládé Israẹli 2wí pé:

“ ‘Èwo nínú abo kìnnìún ni ìyá rẹ̀ ní àárín àwọn kìnnìún yòókù?

Ó sùn ní àárín àwọn ọ̀dọ́ kìnnìún ó sì ń tọ́jú àwọn ọmọ rẹ̀.

3Ó sì tọ́ ọ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀ dàgbà, ó sì di kìnnìún tó ní agbára,

ó kọ́ ọ láti ṣọdẹ, ó sì ń pa àwọn ènìyàn jẹ.

4Àwọn orílẹ̀-èdè gbọ́ nípa rẹ̀,

wọ́n sì fi ẹ̀wọ̀n mú un nínú iho wọn.

Wọn fi ẹ̀wọ̀n mu nu lọ sí ilẹ̀ Ejibiti.

5“ ‘Nígbà tí abo kìnnìún yìí rí pé ìrètí rẹ̀ sì jásí asán,

ó mú ọmọ rẹ̀ mìíràn ó sì tún tọ́ ọ dàgbà di kìnnìún tó ní agbára.

6Ó sì ń rìn káàkiri láàrín àwọn kìnnìún nítorí pé ó ti lágbára,

o kọ ọdẹ ṣíṣe, ó sì pa àwọn ènìyàn.

7Ó sì wó odi wọn palẹ̀ ó sì sọ àwọn ìlú wọn di ahoro.

Ilẹ̀ náà àti àwọn olùgbé ibẹ̀ sì wà ní ìpayà nítorí bíbú ramúramù rẹ̀.

8Nígbà náà ni àwọn orílẹ̀-èdè dìde sí i,

àwọn tó yìí ká láti ìgbèríko wá.

Wọn dẹ àwọ̀n wọn fún un,

wọn sì mú nínú ihò wọn.

9Wọn fi ìwọ̀ gbé e sínú àgò, wọn mú un lọ sí ọ̀dọ̀ ọba Babeli,

wọn fi sínú ìhámọ́, a kò sì gbọ́ bíbú rẹ̀ mọ́ lórí òkè Israẹli.

10“ ‘Ìyá rẹ dàbí àjàrà nínú ọgbà àjàrà rẹ̀;

tí á gbìn sí etí odò ó, kún fún èso,

ó sì kún fún ẹ̀ka nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ omi,

11Àwọn ẹ̀ka rẹ̀ lágbára tó láti fi ṣe ọ̀pá àṣẹ ìjòyè,

ó ga sókè láàrín ewé rẹ̀,

gíga rẹ̀ hàn jáde láàrín ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀ka rẹ̀.

12Ṣùgbọ́n ó fà á tu ní ìrunú,

á sì wọ́ ọ lulẹ̀,

afẹ́fẹ́ láti ìlà-oòrùn sì gbé èso rẹ̀,

ọ̀pá líle rẹ̀ ti ṣẹ́, ó sì rọ

iná sì jó wọn run.

13Báyìí, a tún ún gbìn sínú aṣálẹ̀

ni ilẹ̀ gbígbẹ àti ilẹ̀ tó ń pòǹgbẹ omi.

14Iná sì jáde láti ọ̀kan lára ẹ̀ka rẹ̀

ó sì pa ẹ̀ka àti èso rẹ̀ run,

dé bi pé kò sí ẹ̀ka tó lágbára lórí rẹ̀ mọ́;

èyí to ṣe fi ṣe ọ̀pá fún olórí mọ́.’

Èyí ni orin ọ̀fọ̀ a o sì máa lo bí orin ọ̀fọ̀.”