Salmo 87
Salmo de los hijos de Coré. Cántico.
1Los cimientos de la ciudad de Dios87:1 Los cimientos de la ciudad de Dios. Lit. Los cimientos de él.
están en el santo monte.
2El Señor ama las entradas de Sión
más que todas las moradas de Jacob.
3De ti, ciudad de Dios,
se dicen cosas gloriosas: Selah
4«Entre los que me reconocen
puedo contar a Rahab y a Babilonia,
a Filistea y a Tiro, lo mismo que a Cus.
Se dice: “Este nació en Sión”».
5De Sión se dirá, en efecto:
«Este y aquel nacieron en ella.
El Altísimo mismo la ha establecido».
6El Señor anotará en el registro de los pueblos:
«Este nació en Sión». Selah
7Y mientras cantan y bailan, dicen:
«En ti se hallan todos mis orígenes».87:7 todos mis orígenes. Lit. todas mis fuentes.
Saamu 87
Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Orin.
1Ó ti fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ sórí òkè mímọ́;
2Olúwa fẹ́ràn ẹnu-ọ̀nà Sioni
ju gbogbo ibùgbé Jakọbu lọ.
3Ohun ológo ni a sọ nípa rẹ̀,
ìlú Ọlọ́run;
4“Èmi ó dárúkọ Rahabu àti Babeli
láàrín àwọn tí ó jẹ́wọ́ mi:
Filistia pẹ̀lú, àti Tire, pẹ̀lú Kuṣi
yóò sọ pé, ‘Èyí ni a bí ní Sioni.’ ”
5Nítòótọ́, ti Sioni ni a ó sọ,
“Eléyìí àti eléyìí ni a bí nínú rẹ̀,
àti Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo ni yóò fìdí rẹ̀ múlẹ̀.”
6Olúwa yóò kọ nínú àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀:
“Eléyìí ni a bí ní Sioni.”
7Àti àwọn olórin àti àwọn tí ń lu
ohun èlò orin yóò wí pé,
“Gbogbo orísun mi ń bẹ nínú rẹ.”