約翰一書 5 – CCBT & YCB

Chinese Contemporary Bible (Traditional)

約翰一書 5:1-21

勝過世界的人

1每一個信耶穌是基督的人,都是從上帝生的。凡愛生他之上帝的,也愛上帝所生的。 2當我們愛上帝,遵行祂的命令時,便知道自己也愛祂的兒女。 3因為我們遵行上帝的命令就是愛上帝,祂的命令並不難遵守。 4因為凡是從上帝生的人都能勝過世界,使我們得勝的是我們的信心。 5誰能勝過世界呢?不就是那些信耶穌是上帝的兒子的人嗎?

上帝的見證

6耶穌基督是藉著水和血來的。祂不單是藉著水來的,也是藉著水和血來的,並且有聖靈為祂做見證,聖靈就是真理。 7這樣,做見證的共有三樣: 8聖靈、水和血。這三者是一致的。 9我們既然接受人的見證,就更該接受上帝的見證,因為上帝為祂的兒子作了見證。 10信上帝兒子的人心裡有這見證,不信上帝的人等於把上帝當作撒謊的,因為他不信上帝為祂兒子做的見證。 11這見證就是:上帝已經把永恆的生命賜給我們,這生命在祂兒子裡面。 12人有上帝的兒子,就有這生命;沒有上帝的兒子,就沒有這生命。

永恆的生命

13我把這些事寫給你們這些信上帝兒子之名的人,是要你們知道自己有永生。 14我們若按著上帝的旨意祈求,祂必垂聽,這是我們對上帝的信心。 15我們既然知道上帝垂聽我們一切的祈求,就知道我們能得到所求的。

16若有人看見信徒犯了不至於死的罪,就當為他禱告,上帝必將生命賜給他。有的罪會導致死亡,我並不是說你們要為這樣的罪禱告。 17一切不義的事都是罪,但有的罪不會導致死亡。

18我們知道從上帝生的不會繼續犯罪,因為上帝的兒子保護他,那惡者無法害他。 19我們知道自己屬於上帝,全世界都在那惡者手中。

20我們知道上帝的兒子已經來了,並且賜給了我們悟性,使我們能認識真神。我們在真神裡面,就是在祂兒子耶穌基督裡面。祂是真神,也是永生。

21孩子們啊,你們要遠離偶像!

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

1 Johanu 5:1-21

Ìgbàgbọ́ nínú ọmọ Ọlọ́run

15.1: Jh 8.42.Olúkúlùkù ẹni tí ó bá gbàgbọ́ pé Jesu ni Kristi, a bí i nípa ti Ọlọ́run: àti olúkúlùkù ẹni tí ó fẹ́ràn. Ẹni tí ó bi nì, ó fẹ́ràn ẹni tí a bí nípasẹ̀ rẹ̀ pẹ̀lú. 2Nípa èyí ni àwa mọ̀ pé àwa fẹ́ràn àwọn ọmọ Ọlọ́run, nígbà tí a bá fẹ́ràn Ọlọ́run, tí a sì ń pa òfin rẹ̀ mọ́. 35.3: Jh 14.15; 1Jh 2.5; 2Jh 6.Nítorí èyí ni ìfẹ́ Ọlọ́run, pé kí àwa pa òfin rẹ̀ mọ́: òfin rẹ̀ kò sì nira, 45.4: Jh 16.33.nítorí olúkúlùkù ẹni tí a bí nípa tí Ọlọ́run, ó ṣẹ́gun ayé. Èyí sì ni ìṣẹ́gun tí ó ṣẹ́gun ayé, àní ìgbàgbọ́ wa. 5Ta ni ẹni tí ó ṣẹ́gun ayé, bí kò ṣe ẹni tí ó gbàgbọ́ pé Ọmọ Ọlọ́run ni Jesu jẹ́?

65.6-8: Jh 19.34; 4.23; 15.26.Èyí ni ẹni tí ó wá nípa omi àti ẹ̀jẹ̀, Jesu Kristi, kì í ṣe nípa omi nìkan, bí kò ṣe nípa omi àti ẹ̀jẹ̀. Àti pé Ẹ̀mí ni ó sì ń jẹ́rìí, nítorí pé òtítọ́ ni Ẹ̀mí. 7Nítorí pé àwọn mẹ́ta ni ó ń jẹ́rìí. 8Ẹ̀mí, omi, àti ẹ̀jẹ̀: àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta sì wà ni ìṣọ̀kan. 95.9: Jh 5.32,36; 8.18.Bí àwa ba ń gba ẹ̀rí ènìyàn, ẹ̀rí Ọlọ́run tóbi jù: nítorí ẹ̀rí Ọlọ́run ni èyí pé, Ó tí jẹ́rìí ní ti Ọmọ rẹ̀. 105.10: 1Jh 1.10.Ẹni tí ó bá gba Ọmọ Ọlọ́run gbọ́, ó ni ẹ̀rí nínú ara rẹ̀; ẹni tí kò bá gba Ọlọ́run gbọ́, ó ti mú un ni èké; nítorí kò gba ẹ̀rí náà gbọ́ tí Ọlọ́run jẹ́ ní ti Ọmọ rẹ̀. 11Ẹ̀rí náà sì ni èyí pé Ọlọ́run fún wa ní ìyè àìnípẹ̀kun, ìyè yìí sì ń bẹ nínú Ọmọ rẹ̀. 125.12: Jh 3.36.Ẹni tí ó bá ni Ọmọ, ó ni ìyè; ẹni tí kò bá sì ni Ọmọ Ọlọ́run, kò ní ìyè.

Àwọn àfiyèsí ìparí

135.13: Jh 20.31.Nǹkan wọ̀nyí ni mo kọ̀wé rẹ̀ sí yín, àní sí ẹ̀yin tí ó gba orúkọ Ọmọ Ọlọ́run gbọ́; kí ẹ̀yin lè mọ̀ pé ẹ̀yin ní ìyè àìnípẹ̀kun, àní fún ẹ̀yin tí ó gba orúkọ Ọmọ Ọlọ́run gbọ́. 145.14: Mt 7.7; 1Jh 3.21.Èyí sì ni ìgboyà tí àwa ní níwájú rẹ̀, pé bí àwa bá béèrè ohunkóhun gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ rẹ̀, ó ń gbọ́ tí wa; 15Bí àwa bá sì mọ̀ pé ó ń gbọ́ tí wa, ohunkóhun tí àwa bá béèrè, àwa mọ̀ pé àwa rí ìbéèrè tí àwa ti béèrè lọ́dọ̀ rẹ̀ gbà.

16Bí ẹnikẹ́ni bá rí arákùnrin rẹ̀ tí ń dẹ́ṣẹ̀ tí kì í ṣe sí ikú, òun yóò béèrè, Ọlọ́run yóò sì fún un ni ìyè, àní, fún àwọn tí ń dẹ́ṣẹ̀ tí kì í ṣe sí ikú. Ẹ̀ṣẹ̀ kan ń bẹ sì ikú: èmi kò wí pé ki òun gbàdúrà fún èyí. 17Gbogbo àìṣòdodo ni ẹ̀ṣẹ̀: ẹ̀ṣẹ̀ kan ń bẹ tí kì í ṣe sí ikú.

185.18: Jh 17.15; 1Jh 3.9.Àwa mọ̀ pé ẹnikẹ́ni tí a bí nípa ti Ọlọ́run kì í dẹ́ṣẹ̀: ṣùgbọ́n ẹni tí a bí nípa tí Ọlọ́run a pa ara rẹ̀ mọ́, ẹni búburú kò ní lè fọwọ́ kàn án. 19Àwa mọ̀ pé tí Ọlọ́run ni wá, àti gbogbo ayé ni ó wà lábẹ́ agbára ẹni búburú náà. 205.20-21: Jh 17.3; If 3.7.Àwa sì mọ̀ pé Ọmọ Ọlọ́run dé, ó sì tí fi òye fún wa, kí àwa lè mọ ẹni tí í ṣe òtítọ́, àwa sì ń bẹ nínú ẹni tí í ṣe òtítọ́, àní, nínú Ọmọ rẹ̀, Jesu Kristi. Èyí ni Ọlọ́run òtítọ́, àti ìyè àìnípẹ̀kun.

21Ẹ̀yin ọmọ mi, ẹ pa ara yín mọ́ kúrò nínú òrìṣà.