彌迦書 4 – CCBT & YCB

Chinese Contemporary Bible (Traditional)

彌迦書 4:1-13

耶路撒冷的將來

1在末後的日子,

耶和華殿所在的山必超乎群山,

高過眾嶺,

萬民都要歸向它。

2多國的民都要前來,說:

「來吧,讓我們登耶和華的山,

雅各之上帝的殿。

祂必指示我們當行的路,

我們也要遵行祂的道。」

因為訓誨必出於錫安

耶和華的話語必來自耶路撒冷

3祂要在各民族中施行審判,

為遠方的強國斷定是非。

他們要把刀劍鑄成犁頭,

把矛槍打成鐮刀。

國與國之間不再動刀槍,

也不再學習戰爭。

4人人都安然坐在自己的葡萄樹和無花果樹下,

不再擔驚受怕。

這是萬軍之耶和華親口說的。

5萬民都遵從自己的神明,

但我們要永遠遵從我們的上帝耶和華。

6耶和華說:

「到那日,我要聚集瘸腿的,

招聚被擄的和被我懲罰的。

7我要使瘸腿的成為餘民,

讓被擄的成為強國。

耶和華要在錫安山做王治理他們,

從那時直到永遠。

8「你這羊群的瞭望塔,

錫安4·8 」希伯來文是「女子」,可能是對錫安的暱稱,下同4·13的堅壘啊!

從前的國權——

耶路撒冷城的王位必重新歸你。」

9現在你為何大聲哭喊?

是因為你沒有王嗎?

難道你的謀士都死了嗎,

以致你像分娩的婦人一樣痛苦不堪?

10錫安的百姓啊,

你們要像分娩的婦人一樣輾轉呻吟,

因為你們現在要離開這城,

住在荒野,被擄到巴比倫

在那裡,你們將得到解救;

在那裡,耶和華必從敵人手中救贖你們。

11現在許多國家一起來攻擊你們,說:

「願錫安遭蹂躪,

我們要看著錫安被毀滅。」

12他們卻不知道耶和華的心意,

也不明白祂的計劃。

祂聚集他們是要懲罰他們,

像把禾捆堆積在麥場一樣。

13耶和華說:

錫安城啊,

起來打穀吧!

我要給你鐵角,

我要給你銅蹄。

你要打碎列國,

將他們的不義之財獻給耶和華,

把他們的財富獻給普天下的主。」

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Mika 4:1-13

Òkè Olúwa

14.1-3: Isa 2.2-4.Ní ọjọ́ ìkẹyìn

a ó fi òkè ilé Olúwa lélẹ̀ lórí àwọn òkè ńlá,

a ó sì gbé e ga ju àwọn òkè kéékèèkéé lọ,

àwọn ènìyàn yóò sì máa wọ̀ sínú rẹ̀.

2Ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè yóò wá,

wọn yóò sì wí pé, “Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí á gòkè ńlá Olúwa,

àti sí ilé Ọlọ́run Jakọbu

Òun yóò sì kọ́ wa ní ọ̀nà rẹ̀,

kí àwa kí ó lè rìn ní ọ̀nà rẹ̀.”

Òfin yóò jáde láti Sioni wá,

àti ọ̀rọ̀ Olúwa láti Jerusalẹmu.

3Òun yóò sì ṣe ìdájọ́ láàrín ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn,

yóò sì parí aáwọ̀ fún orílẹ̀-èdè alágbára jíjìn réré.

Wọn yóò sì fi idà wọn rọ ohun èlò ìtulẹ̀

àti ọ̀kọ̀ wọn di dòjé

orílẹ̀-èdè kì yóò gbé idà sókè sí orílẹ̀-èdè mọ́,

bẹ́ẹ̀ ni wọn kì yóò kọ́ ogun jíjà mọ́.

44.4: Sk 3.10.Ṣùgbọ́n olúkúlùkù yóò jókòó lábẹ́ àjàrà rẹ̀

àti lábẹ́ igi ọ̀pọ̀tọ́ rẹ̀,

ẹnìkan kì yóò sì dẹ́rùbà wọ́n,

nítorí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti sọ̀rọ̀.

5Gbogbo àwọn ènìyàn ń rìn,

olúkúlùkù ni orúkọ ọlọ́run tirẹ̀,

ṣùgbọ́n àwa yóò máa rìn ní orúkọ Olúwa.

Ọlọ́run wa láé àti láéláé.

Èrò Olúwa

6“Ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí,

“Èmi yóò kó àwọn arọ jọ;

èmi yóò sì ṣà àwọn tí a lé kúrò ní ìlú jọ,

àti àwọn ẹni tí èmi ti pọ́n lójú.

7Èmi yóò dá àwọn arọ sí fún èyí tókù,

èmi yóò sì sọ àwọn tí a lé kúrò ní ìlú di orílẹ̀-èdè alágbára.

Olúwa yóò sì jẹ ọba lórí wọn ní òkè ńlá Sioni

láti ìsinsin yìí lọ àti títí láéláé.

8Ní ti ìwọ, ilé ìṣọ́ agbo àgùntàn,

odi alágbára ọmọbìnrin Sioni,

a ó mú ìjọba ìṣáájú padà bọ̀ sípò fún un yín;

ìjọba yóò sì wà sí ọ̀dọ̀ ọmọbìnrin Jerusalẹmu.”

9Kí ni ìwọ ha ń kígbe sókè sí nísinsin yìí?

Ǹjẹ́ ìwọ kò ní ọba bí?

Àwọn ìgbìmọ̀ rẹ ṣègbé bí?

Nítorí ìrora ti dì ọ́ mú bí obìnrin tí ń rọbí.

10Máa yí síhìn-ín sọ́hùn-ún nínú ìrora,

ìwọ obìnrin Sioni,

bí ẹni tí ń rọbí,

nítorí nísinsin yìí ìwọ yóò jáde lọ kúrò ní ìlú,

ìwọ yóò sì máa gbé inú igbó.

Ìwọ yóò lọ sí Babeli;

níbẹ̀ ni ìwọ yóò sì ti rí ìgbàlà.

Níbẹ̀ ni Olúwa yóò ti rà ọ́ padà kúrò lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá rẹ.

11Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè kó ara wọn jọ sí ọ.

Wọ́n sì wí pé, “Ẹ jẹ́ kí a sọ ọ́ di àìmọ́,

Ẹ jẹ́ kí ojú wa kí ó wo Sioni!”

12Ṣùgbọ́n wọn kò mọ

èrò inú Olúwa;

Bẹ́ẹ̀ ni òye ìmọ̀ rẹ̀ kò yé wọn,

nítorí ó ti kó wọn jọ bí i ìtí sínú ìpakà.

13“Dìde, kí ó sì máa pa ọkà ìwọ ọmọbìnrin Sioni,

nítorí èmi yóò sọ ìwo rẹ̀ di irin,

èmi yóò sì sọ pátákò rẹ̀ di idẹ

ìwọ yóò run ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè pátápátá.”

Èmi yóò sì ya èrè wọn sọ́tọ̀ fún Olúwa

àti ọrọ̀ wọn sí Olúwa gbogbo ayé.