帖撒羅尼迦後書 1 – CCBT & YCB

Chinese Contemporary Bible (Traditional)

帖撒羅尼迦後書 1:1-12

1保羅西拉提摩太寫信給帖撒羅尼迦屬於我們父上帝和主耶穌基督的教會。

2願我們的父上帝和主耶穌基督賜給你們恩典和平安!

感恩與勸勉

3弟兄姊妹,我們應當為你們常常感謝上帝,這是合宜的,因為你們的信心不斷增長,彼此相愛的心也不斷增加。 4因此,我們在上帝的眾教會中誇獎你們在各種迫害和患難中的堅忍和信心。 5你們這種表現正是上帝公義審判的明證,使你們配進上帝的國,你們正在為這國受苦。

6上帝是公義的,祂必以患難來報應那些迫害你們的人。 7當主耶穌和祂大能的天使在烈焰中從天上顯現時,祂必使你們這些受苦的人和我們同得安慰, 8懲罰那些不認識上帝、不聽從有關我們主耶穌之福音的人。 9那些人要受的刑罰就是離開主的面和祂榮耀的權能,永遠滅亡。 10主降臨的那日,祂要在祂的眾聖徒中得到榮耀,使所有的信徒驚歎不已。你們也會在當中,因為你們相信了我們做的見證。

11因此,我們常常為你們禱告,願我們的上帝看你們配得祂的呼召,用大能成全你們一切美好的心願和憑信心所做的工作。 12這樣,按照我們的上帝和主耶穌基督所賜的恩典,主耶穌基督的名便在你們身上得到榮耀,你們也在祂身上得到榮耀。

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

2 Tẹsalonika 1:1-12

11.1: 1Tẹ 1.1; 2Kọ 1.19; Ap 16.1.Paulu, Sila àti Timotiu,

Sí ìjọ Tẹsalonika, nínú Ọlọ́run Baba wa àti Jesu Kristi Olúwa:

21.2: Ro 1.7.Oore-ọ̀fẹ́ àti àlàáfíà fún yín láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run baba àti Jesu Kristi Olúwa.

Àdúrà àti ìdúpẹ́

31.3: 1Tẹ 1.2.Ó yẹ kí a máa dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run nígbà gbogbo nítorí yín, ará, àní gẹ́gẹ́ bí ó ti yẹ, nítorí pé ìgbàgbọ́ yín ń dàgbà gidigidi, àti ìfẹ́ olúkúlùkù yín sí ara yín ń di púpọ̀. 4Nítorí náà, àwa tìkára wa ń fi yín ṣògo nínú ìjọ Ọlọ́run, nítorí sùúrù àti ìgbàgbọ́ yín nínú gbogbo inúnibíni àti wàhálà yín tí ẹ̀yin náà ń fi ara dà.

5Àwọn nǹkan wọ̀nyí jẹ́ ẹ̀rí pé òdodo ni ìdájọ́ Ọlọ́run àti pé nítorí èyí ni a ó kà yín yẹ fún ìjọba Ọlọ́run, nítorí èyí tí ẹ̀yin pẹ̀lú ṣe ń jìyà. 6Olódodo ni Ọlọ́run: Òun yóò pọ́n àwọn tí ń pọ́n yín lójú, lójú, 7Òun yóò sì fi ìtura fún ẹ̀yin tí a ti pọ́n lójú àti fún àwa náà pẹ̀lú. Èyí yóò sì ṣe nígbà ìfarahàn Jesu Olúwa láti ọ̀run wá fún wá nínú ọwọ́ iná pẹ̀lú àwọn angẹli alágbára. 81.8: Ga 4.8.Òun yóò fi ìyà jẹ àwọn tí kò mọ Ọlọ́run àti àwọn tí ń ṣe àìgbọ́ràn sí ìhìnrere Jesu Olúwa wa. 9A ó fi ìparun àìnípẹ̀kun jẹ wọ́n ní yà, a ó sì ṣe wọn mọ̀ kúrò níwájú Olúwa àti inú ògo agbára rẹ̀ 10Ní ọjọ́ tí yóò jẹ́ ẹni tí a ó yìn lógo nínú àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ àti ẹni àwòyanu ní àárín gbogbo àwọn tí ó ti gbàgbọ́. Èyí kò yọ yín sílẹ̀, nítorí ẹ ti gba ẹ̀rí tí a jẹ́ sí yín gbọ́.

111.11: 1Tẹ 1.3.Nítorí èyí, àwa pẹ̀lú ń gbàdúrà fún un yín nígbà gbogbo, pé kí Ọlọ́run wa kí ó lè kà yín yẹ fún ìpè rẹ̀, àti pé nípa agbára rẹ̀, òun yóò mú gbogbo èrò rere yín ṣẹ àti gbogbo ohun tí ìgbàgbọ́ bá rú jáde. 12Wọ̀nyí ni àdúrà wa, kí orúkọ Jesu Olúwa wa lè di yíyìn lógo nínú yín àti ẹ̀yin nínú rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run àti ti Jesu Kristi Olúwa.