希伯來書 3 – CCBT & YCB

Chinese Contemporary Bible (Traditional)

希伯來書 3:1-19

耶穌超越摩西

1因此,同蒙天召的聖潔的弟兄姊妹,你們應當仔細思想那位我們公認為特使和大祭司的耶穌。 2祂向委任祂的上帝盡忠,就好像摩西向上帝的全家盡忠一樣。 3然而祂卻比摩西配得更大的榮耀,因為建造房子的人當然比房子更尊貴。 4所有的房子都有建造者,但建造萬物的是上帝。 5摩西以僕人的身分向上帝的全家盡忠,為將來要宣告的事做見證。 6但基督是以兒子的身分忠心治理上帝的家。我們若堅強勇敢,持定引以為榮的盼望,我們就是祂的家了。

不可存剛硬的心

7因此,正如聖靈說:

「你們今天若聽見祂的聲音,

8不可心裡頑固,

像從前在曠野試探祂、悖逆祂一樣。

9當時,你們的祖先試我、探我,

觀看我的作為達四十年之久。

10所以,我向那世代的人發怒,

說,『他們總是執迷不悟,

不認識我的道路。』

11我就在憤怒中起誓說,

『他們絕不可進入我的安息。』」

12弟兄姊妹,要謹慎,免得你們當中有人心存惡念,不肯相信,背棄了永活的上帝。 13趁著還有今日,要天天互相勸勉,免得有人被罪迷惑,心裡變得剛硬。 14如果我們將起初的信念堅持到底,便在基督裡有份了。

15聖經上說:

「你們今日若聽見祂的聲音,

不可像從前那樣硬著心悖逆祂。」

16聽見祂的聲音卻又悖逆祂的是誰呢?不就是摩西埃及領出來的那些人嗎? 17四十年之久惹上帝發怒的是誰呢?不就是那些犯罪作惡並倒斃在曠野的人嗎? 18上帝起誓不准誰進入祂的安息呢?不就是那些不肯信從的人嗎? 19可見,他們不能進入上帝的安息是因為不信的緣故。

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Heberu 3:1-19

Jesu pọ̀ ju Mose lọ

1Nítorí náà ẹ̀yin ará mímọ́, alábápín ìpè ọ̀run, ẹ gba ti aposteli àti olórí àlùfáà ìjẹ́wọ́ wa rò, àní Jesu; 23.2: Nu 12.7.Ẹni tí o ṣe olóòtítọ́ si ẹni tí ó yàn án, bí Mose pẹ̀lú tí ṣe olóòtítọ́ nínú iṣẹ́ rẹ̀ gbogbo nínú ilé Ọlọ́run. 3Nítorí a ka ọkùnrin yìí ni yíyẹ sí ògo ju Mose lọ níwọ̀n bí ẹni tí ó kọ́ ilé ti lọ́lá ju ilé lọ. 4Láti ọwọ́ ènìyàn kan ni a sá à ti kọ́ olúkúlùkù ilé; ṣùgbọ́n ẹni tí ó kọ́ ohun gbogbo ni Ọlọ́run. 53.5: Nu 12.7.Mose nítòótọ́ sì ṣe olóòtítọ́ nínú gbogbo iṣẹ́ rẹ̀ nínú ilé Ọlọ́run, bí ìránṣẹ́, fún ẹ̀rí ohun tí a ó sọ̀rọ̀ wọ́n ní ìgbà ìkẹyìn. 6Ṣùgbọ́n Kristi jẹ́ olóòtítọ́ gẹ́gẹ́ bí ọmọ lórí ilé Ọlọ́run; ilé ẹni tí àwa jẹ́, bí àwa bá gbẹ́kẹ̀lé e, tí a sì di ìṣògo ìrètí wa mu ṣinṣin títí dé òpin.

Ìkìlọ̀ fún aláìgbàgbọ́

73.7-11: Sm 95.7-11.Nítorí náà gẹ́gẹ́ bi Ẹ̀mí Mímọ́ tí wí:

“Lónìí bí ẹ̀yin bá gbọ́ ohùn rẹ̀,

8Ẹ má ṣe sé ọkàn yín le,

bí ìgbà ìṣọ̀tẹ̀,

bí i ní ọjọ́ ìdánwò ní aginjù:

9Níbi tí àwọn baba yín ti dán mi wò,

tí wọ́n sì rí iṣẹ́ mi ní ogójì ọdún.

10Nítorí náà a mú inú bí mi si ìran náà,

mo sì wí pé, ‘Nígbà gbogbo ni wọn ṣìnà ní ọkàn wọn;

wọn kò sì mọ ọ̀nà mi.’

11Bí mo tí búra nínú ìbínú mi,

‘wọn kí yóò wọ inú ìsinmi mi.’ ”

12Ẹ kíyèsára, ará, kí ọkàn búburú ti àìgbàgbọ́ má ṣe wà nínú ẹnikẹ́ni yín, ní lílọ kúrò lọ́dọ̀ Ọlọ́run alààyè. 13Ṣùgbọ́n ẹ máa gba ara yín ní ìyànjú ní ojoojúmọ́, níwọ̀n ìgbà tí a bá ń pè ní “Òní,” kí a má ba à sé ọkàn ẹnikẹ́ni nínú yín le nípa ẹ̀tàn ẹ̀ṣẹ̀. 14Nítorí àwa di alábápín pẹ̀lú Kristi, bí àwa bá di ìpilẹ̀ṣẹ̀ ìgbẹ́kẹ̀lé wa mú ṣinṣin títí dé òpin; 153.15: Sm 95.7-8.Nígbà tí a ń wí pé:

“Lónìí bí ẹ̀yin bá gbọ́ ohùn rẹ̀,

ẹ má sé ọkàn yin le,

bí ìgbà ìṣọ̀tẹ̀.”

163.16-19: Nu 14.1-35.Àwọn ta ni ó gbọ́ tí ó sì tún ṣọ̀tẹ̀? Kì í ha ṣe gbogbo àwọn tí o jáde kúrò ní Ejibiti ní abẹ́ àkóso Mose? 173.17: Nu 14.29.Àwọn ta ni ó sì bínú sí fún ogójì ọdún? Kì í ha ṣe sí àwọn tí ó dẹ́ṣẹ̀, òkú àwọn tí ó sùn ní aginjù? 18Àwọn wo ni ó búra fún pé wọn kì yóò wọ inú ìsinmi òun, bí kò ṣe fún àwọn tí ó ṣe àìgbọ́ràn? 19Àwa sì rí i pé wọn kò lè wọ inú rẹ̀ nítorí àìgbàgbọ́.