诗篇 95 – CCB & YCB

Chinese Contemporary Bible (Simplified)

诗篇 95:1-11

第 95 篇

赞美上帝之歌

1来吧,让我们向耶和华歌唱,

向拯救我们的磐石欢呼。

2让我们怀着感恩的心来到祂面前,

向祂高唱赞美诗。

3因为耶和华是伟大的上帝,

是众神明之上的大君王。

4祂掌管地的深处,

祂拥有山的高峰。

5海洋属于祂,是祂创造的,

陆地也是祂造的。

6来吧,让我们俯伏敬拜,

在创造我们的耶和华面前跪下。

7因为祂是我们的上帝,

我们是祂照管的子民,

是祂牧放的羊群。

你们今日若听见祂的声音,

8不可像你们祖先在米利巴

在旷野的玛撒那样心里顽固。

9耶和华说:“虽然他们见过我的作为,

却仍然试探我。

10所以,我憎恶他们四十年之久,

我说,‘他们偏离正路,不遵行我的命令。’

11因此我在怒中起誓说,

‘他们绝不可进入我的安息!’”

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 95:1-11

Saamu 95

1Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a kọ orin ayọ̀ sí Olúwa

Ẹ jẹ́ kí a kígbe sókè sí àpáta ìgbàlà wa.

2Ẹ jẹ́ kí a wá sí iwájú rẹ̀ pẹ̀lú ọpẹ́

kí a sì pòkìkí rẹ̀ pẹ̀lú ohun èlò

orin àti ìyìn.

3Nítorí Olúwa Ọlọ́run títóbi ni,

ọba tí ó tóbi ju gbogbo òrìṣà lọ.

4Ní ọwọ́ rẹ̀ ni ọ̀gbun ilẹ̀ wà,

ṣóńṣó orí òkè tirẹ̀ ní ṣe.

5Tirẹ̀ ni Òkun, nítorí òun ni ó dá a

àti ọwọ́ rẹ̀ ni ó fi dá ìyàngbẹ ilẹ̀.

6Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a foríbalẹ̀ kí a sìn ín,

Ẹ jẹ́ kí a kúnlẹ̀ níwájú

Olúwa ẹni tí ó dá wa;

795.7-11: Hb 3.7-11; 4.3-11.Nítorí òun ni Ọlọ́run wa

àwa sì ni ènìyàn pápá rẹ̀,

àti ọ̀wọ́ ẹran ni abẹ́ ìpamọ́ rẹ̀.

Lónìí tí ìwọ bá gbọ́ ohùn rẹ̀,

8“Ẹ má ṣe sé ọkàn yín le gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ṣe ní Meriba,

àti bí ẹ ti ṣe ní ọjọ́ náà ní Massa ní aginjù,

9Nígbà tí àwọn baba yín dán mi wò

tí wọn wádìí mi,

tí wọn sì rí iṣẹ́ mi

10Fún ogójì ọdún ni èmi fi bínú sí ìran náà;

mo wí pé, ‘Wọ́n jẹ́ ènìyàn tí ọkàn wọn ṣáko lọ

wọn kò sì mọ ọ̀nà mi.’

11Nítorí náà ni mo kéde ìbúra nínú ìbínú mi

‘Wọn kì yóò wọ ibi ìsinmi mi.’ ”