诗篇 88 – CCB & YCB

Chinese Contemporary Bible (Simplified)

诗篇 88:1-18

第 88 篇

求上帝眷顾

可拉后裔的诗,就是以斯拉人希幔的训诲诗,交给乐长,调用“麻哈拉利暗俄”88:0 麻哈拉利暗俄”意为“受苦”。

1耶和华,拯救我的上帝啊,

我昼夜不停地呼求你。

2求你垂听我的祷告,

倾听我的呼求。

3我饱经患难,

生命在死亡的边缘。

4我被列在下坟墓的人中,

我的精力耗尽。

5我被扔在死人中,

如同被杀的人躺在坟墓里,

被你遗忘,不再蒙你眷顾。

6你已经把我扔在漆黑的深渊。

7你的烈怒重重地压着我,

如汹涌波涛把我淹没。(细拉)

8你使我众叛亲离,遭人唾弃。

我陷入困境,无路可逃。

9我的眼睛因哭泣而视力模糊。

耶和华啊,我天天呼求你,

举手向你呼求。

10你要行神迹给死人看吗?

死人会起来赞美你吗?(细拉)

11坟墓里的死人怎能宣扬你的慈爱呢?

灭亡的人怎能传扬你的信实呢?

12黑暗之地有谁知道你的神迹呢?

在被遗忘之地有谁知道你的公义作为呢?

13耶和华啊,我向你呼求,

我在清晨向你祷告。

14耶和华啊,你为何弃绝我?

为何掩面不理我?

15我从小受苦,几乎丧命。

你使我惊恐不已,陷入绝望。

16你的烈怒吞噬了我,

你可怕的攻击毁灭了我。

17这些灾难如洪涛整天环绕我,

彻底围住我。

18你使我的亲朋好友离我而去,

只有黑暗与我相伴。

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 88:1-18

Saamu 88

Orin. Saamu ti àwọn ọmọ Kora. Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti mahalati leannoti. Maskili ti Hemani ará Esra.

1Olúwa, Ọlọ́run tí ó gbà mí là,

ní ọ̀sán àti ní òru ni mo kígbe sókè sí Ọ.

2Jẹ́ kí àdúrà mi kí ó wá sí iwájú rẹ;

dẹ etí rẹ sí igbe mi.

3Nítorí ọkàn mi kún fún ìpọ́njú

ọkàn mi sì súnmọ́ isà òkú.

4A kà mí mọ́ àwọn tí wọ́n lọ sí ọ̀gbun ilẹ̀

èmi dàbí ọkùnrin tí kò ni agbára.

5A yà mí sọ́tọ̀ pẹ̀lú àwọn òkú

bí ẹni tí a pa tí ó dùbúlẹ̀ ní ipò ikú,

ẹni tí ìwọ kò rántí mọ́,

ẹni tí a gé kúrò lára àwọn tí ìwọ ń tọ́jú.

6Ìwọ tí ó fi mí sí kòtò jíjìn,

ní ibi ọ̀gbun tó ṣókùnkùn.

7Ìbínú rẹ ṣubú lé mi gidigidi;

ìwọ ti fi àwọn ìjì rẹ borí mi.

8Ìwọ tí gba ọ̀rẹ́ mi tí ó súnmọ́ mi kúrò lọ́wọ́ mi

ìwọ sì sọ mi di ìríra sí wọn.

A há mi mọ́, èmi kò sì le è jáde;

9Ojú mi káàánú nítorí ìpọ́njú.

Mo kígbe pè ọ́, Olúwa, ní gbogbo ọjọ́;

mo na ọwọ́ mi jáde sí ọ.

10Ìwọ ó fi iṣẹ́ ìyanu rẹ hàn fún òkú bi?

Àwọn òkú yóò ha dìde láti yìn ọ́ bí?

11A ó ha fi ìṣeun ìfẹ́ rẹ hàn ní ibojì bí:

Tàbí òtítọ́ rẹ ní ipò ìparun?

12A ha lè mọ iṣẹ́ ìyanu rẹ ní òkùnkùn bí

àti òdodo rẹ ní ilẹ̀ ìgbàgbé?

13Ṣùgbọ́n mo kígbe sí ọ fún ìrànlọ́wọ́, Olúwa;

ní òwúrọ̀ ni àdúrà mí wá sọ́dọ̀ rẹ.

14Olúwa, èéṣe tí ìwọ fi kọ̀ mí

tí ìwọ fi ojú rẹ pamọ́ fún mi?

15Láti ìgbà èwe mi, ìṣẹ́ ń ṣẹ́ mi,

èmi múra àti kú;

nígbà tí ẹ̀rù rẹ bá ń bà mí,

èmi di gbére-gbère

16Ìbínú rẹ ti kọjá lára mi;

ìbẹ̀rù rẹ ti gé mi kúrò

17Ní gbogbo ọjọ́ ni wọn yí mi ká bí ìkún omi;

wọ́n mù mí pátápátá.

18Ìwọ ti mú ọ̀rẹ́ àti olùfẹ́ mi kúrò lọ́dọ̀ mi;

òkùnkùn sì jẹ́ ọ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ mi.