诗篇 81 – CCB & YCB

Chinese Contemporary Bible (Simplified)

诗篇 81:1-16

第 81 篇

歌颂上帝的恩惠

亚萨的诗,交给乐长,用迦特乐器。

1要歌颂赐我们力量的上帝,

雅各的上帝欢呼。

2要唱诗,击鼓,弹起琴瑟。

3要在我们过节的朔日和望日81:3 朔日和望日”即每月的初一和十五。吹响号角。

4这是以色列的律例,

雅各的上帝所定的法令。

5上帝攻击埃及的时候,

约瑟立下此法度。

我在那里听见陌生的声音说:

6“我卸下了你肩上的重担,

使你的双手不再做苦工,

7你在苦难中向我呼求,

我就拯救了你,

从雷声隆隆的密云中应允了你。

我在米利巴泉边考验你。(细拉)

8我的子民啊,

要听我的警告。

以色列人啊,

但愿你们听从我的话。

9你们断不可供奉别的神明,

也不可向外族的神明下拜,

10我是你们的上帝耶和华,

曾把你们带出埃及

张开你们的口吧,

我必使你们饱足。

11我的子民却不肯听我的话,

以色列不愿意顺从我。

12因此我就任凭他们顽固不化,

为所欲为。

13但愿我的子民肯听从我,

以色列人肯遵行我的道。

14那时,我必迅速制服他们的敌人,

伸手攻击他们的仇敌。

15憎恶我的人要在我面前屈膝投降,永远沉沦。

16我要以上好的麦子供养我的子民,

让他们饱享磐石间的蜂蜜。”

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 81:1-16

Saamu 81

Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti gittiti. Ti Asafu.

1Kọrin sókè sí Ọlọ́run agbára wa

Ẹ hó ìhó ayọ̀ sí Ọlọ́run Jakọbu!

2Ẹ mú orin mímọ́, kí ẹ sì mú ìlù wá,

tẹ dùùrù dídùn pẹ̀lú ohun èlò orin mímọ́.

3Ẹ fún ìpè ní oṣù tuntun

àní nígbà tí a yàn;

ní ọjọ́ àjọ wa tí ó ní ìrònú.

4Èyí ni àṣẹ fún Israẹli,

àti òfin Ọlọ́run Jakọbu.

5Ó fi múlẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìlànà fún Josẹfu

nígbà tí ó la ilẹ̀ Ejibiti já.

Níbi tí a ti gbọ́ èdè tí kò yé wa.

6Ó wí pé, “Mo gbé àjàgà kúrò ní èjìká yín,

a tú ọwọ́ wọn sílẹ̀ kúrò nínú apẹ̀rẹ̀.

7Nínú ìnilára ni ẹ pè mo sì gbà yín là,

mo dá a yín lóhùn nínú ìkọ̀kọ̀ àrá,

mo dán an yín wò ní odò Meriba. Sela.

8“Gbọ́, ẹ̀yin ènìyàn mi, èmi ó sì kìlọ̀ fún un yín,

bí ìwọ bá fetí sí mi, ìwọ Israẹli.

9Ẹ̀yin kì yóò ní Ọlọ́run ilẹ̀ mìíràn láàrín yín;

ẹ̀yin kì yóò foríbalẹ̀ fún Ọlọ́run àjèjì.

10Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ,

ẹni tí ó mú un yín jáde láti Ejibiti.

Ẹ la ẹnu yín gbòòrò, èmi yóò sì kún un.

11“Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi kì yóò gbọ́ tèmi;

Israẹli kò ní tẹríba fún mi.

12Nítorí náà ni mo ṣe fi wọ́n fún ọkàn líle wọn

láti máa rìn ní ọ̀nà ẹ̀tàn wọn.

13“Bí àwọn ènìyàn mi yóò bá gbọ́ tèmi

bí Israẹli yóò bá tẹ̀lé ọ̀nà mi,

14Ní kánkán ni èmi yóò ṣẹ́gun àwọn ọ̀tá wọn

kí n sì yí ọwọ́ mi padà sí ọ̀tá wọn!

15Àwọn tí ó kórìíra Olúwa yóò tẹríba níwájú rẹ̀.

Ìjìyà wọn yóò sì pẹ́ títí láé

16Ṣùgbọ́n a ó fi ọkà tí ó dára bọ́ ọ yín

èmi ó tẹ́ ẹ yín lọ́rùn pẹ̀lú oyin inú àpáta.”