第 41 篇
病中的祷告
大卫的诗,交给乐长。
1善待穷人的有福了!
耶和华必救他们脱离困境。
2耶和华必保护他们,
救他们的性命,
使他们在地上享福,
不让仇敌恶谋得逞。
3他们生病在床,
耶和华必看顾,
使他们康复。
4我祷告说:“耶和华啊,
求你怜悯我,医治我,
因为我得罪了你。”
5我的仇敌恶狠狠地说:
“他何时才会死,
并且被人遗忘呢?”
6他们来看我时,
心怀恶意,满口谎言,
出去后散布流言。
7所有恨我的人都交头接耳,
设计害我。
8他们说:“他患了恶病,
再也起不来了!”
9连我所信赖、吃我饭的挚友也用脚踢我。
10耶和华啊,
求你怜悯我,叫我痊愈,
我好报复他们。
11我知道你喜悦我,
因为你没有让仇敌胜过我。
12你因我正直而扶持我,
让我永远侍立在你面前。
13从亘古到永远,
以色列的上帝耶和华当受称颂。
阿们!阿们!
Saamu 41
Fún adarí orin. Saamu Dafidi.
1Ìbùkún ni fún ẹni tí ó ń ro ti aláìní:
Olúwa yóò gbà á ní ìgbà ìpọ́njú.
2Olúwa yóò dáàbò bò ó yóò sì pa ọkàn rẹ̀ mọ́:
yóò bùkún fún un ní orí ilẹ̀
kò sì ní fi sílẹ̀ fún ìfẹ́ àwọn ọ̀tá rẹ̀.
3Olúwa yóò gbà á lórí àkéte àìsàn rẹ̀
yóò sì mú un padà bọ̀ sípò kúrò nínú àìsàn rẹ̀.
4Ní ti èmi, mo wí pé “Olúwa, ṣàánú fún mi;
wò mí sàn, nítorí pé mo ti ṣẹ̀ sí ọ”.
5Àwọn ọ̀tá mi ń sọ̀rọ̀ mi nínú àrankàn, pé
“Nígbà wo ni yóò kú, ti orúkọ rẹ̀ yóò sì run?”
6Nígbàkígbà tí ẹnìkan bá wá wò mí,
wọn ń sọ̀rọ̀ ẹ̀tàn, nígbà tí àyà rẹ̀ bá kó ẹ̀ṣẹ̀ jọ sí ara rẹ̀;
nígbà tí ó bá jáde lọ yóò sì máa tàn án kálẹ̀.
7Àwọn ọ̀tá mi gbìmọ̀ papọ̀ nípa mi;
èmi ni wọ́n ń gbìmọ̀ ibi sí,
8wọ́n wí pé, “Ohun búburú ni ó dì mọ́ ọn ṣinṣin
àti ní ibi tí ó dùbúlẹ̀ sí,
kì yóò dìde mọ́.”
941.9: Jh 13.18.Pàápàá, ọ̀rẹ́ mi tímọ́tímọ́, ẹni tí mo gbẹ́kẹ̀lé,
ẹni tí ó ń jẹ nínú oúnjẹ mi,
tí gbé gìgísẹ̀ rẹ̀ sókè sí mi.
10Ṣùgbọ́n ìwọ Olúwa, ṣàánú fún mi;
gbé mi sókè, kí ń ba lè san fún wọn.
11Èmi mọ̀ pé inú rẹ̀ dùn sí mi,
nítorí ọ̀tá mi kò borí mi.
12Bí ó ṣe tèmi ni
ìwọ dì mímú nínú ìwà òtítọ́ mi
ìwọ sì gbé mi kalẹ̀ níwájú rẹ títí láé.
13Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli
láé àti láéláé.
Àmín àti Àmín.