诗篇 24 – CCB & YCB

Chinese Contemporary Bible (Simplified)

诗篇 24:1-10

第 24 篇

荣耀的君王

大卫的诗。

1大地和其中的万物都属于耶和华,

世上的一切都是祂的。

2祂把大地奠基于海中,

建立在大水之上。

3谁能登耶和华的山?

谁能站在祂的圣所中?

4只有那些手洁心清,

不拜假神,不起假誓的人。

5他们必蒙耶和华赐福,

被救他们的上帝称为义人。

6这就是寻求耶和华的人,

他们敬拜雅各的上帝。(细拉)

7众城门啊,打开吧!

古老的城门啊,敞开吧!

让荣耀的君王进来。

8谁是荣耀的君王呢?是耶和华,

祂强大无比、战无不胜。

9众城门啊,打开吧!

古老的城门啊,敞开吧!

让荣耀的君王进来。

10谁是荣耀的君王呢?

万军之耶和华是荣耀的君王。(细拉)

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 24:1-10

Saamu 24

Ti Dafidi. Saamu.

124.1: 1Kọ 10.26.Ti Olúwa ni ilẹ̀, àti ẹ̀kún rẹ̀,

ayé àti àwọn tí ó tẹ̀dó sínú rẹ̀;

2Nítorí ó fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ lélẹ̀ lórí Òkun

ó sì gbé e kalẹ̀ lórí àwọn ìṣàn omi.

3Ta ni yóò gun orí òkè Olúwa lọ?

Ta ni yóò dúró ní ibi mímọ́ rẹ̀?

424.4: Mt 5.8.Ẹni tí ó ní ọwọ́ mímọ́ àti àyà funfun,

ẹni tí kò gbé ọkàn rẹ̀ sókè sí asán

tí kò sì búra èké.

5Òun ni yóò rí ìbùkún gbà láti ọ̀dọ̀ Olúwa,

àti òdodo lọ́wọ́ Ọlọ́run ìgbàlà rẹ̀.

6Èyí ni ìran àwọn tí ń ṣe àfẹ́rí rẹ̀,

tí ń ṣe àfẹ́rí rẹ̀, Ọlọ́run Jakọbu. Sela.

7Ẹ gbé orí yín sókè, háà! Ẹ̀yin ọ̀nà;

Kí á sì gbe yín sókè, ẹyin ìlẹ̀kùn ayérayé!

Kí ọba ògo le è wọlé.

8Ta ni ọba ògo náà?

Olúwa tí ó lágbára tí ó sì le,

Olúwa gan an, tí ó lágbára ní ogun.

9Gbé orí yín sókè, ẹyin ọ̀nà;

kí a sì gbé e yín sókè, ẹ̀yin ìlẹ̀kùn ayérayé,

kí Ọba ògo le è wọlé wá.

10Ta ni Ọba ògo náà?

Olúwa àwọn ọmọ-ogun

Òun ni Ọba ògo náà. Sela.