诗篇 12 – CCB & YCB

Chinese Contemporary Bible (Simplified)

诗篇 12:1-8

第 12 篇

祈求上帝帮助

大卫的诗,交给乐长。

1耶和华啊,求你救我们!

因为世上的敬虔人不见了,

忠信的人在人间消失了。

2人人谎话连篇,

花言巧语,口是心非。

3愿你铲除一切花言巧语和狂妄自夸的人。

4他们说:“我们必靠舌头制胜,

嘴唇是我们自己的,

谁管得着我们?”

5耶和华说:“我要保护受欺压的困苦人和哀叹的贫穷人,

使他们如愿以偿。”

6耶和华的应许纯全,

就像在炉中炼过七次的银子。

7耶和华啊,你必保护我们,

永远不容恶人侵害我们。

8众人若抑善扬恶,

恶人必横行无忌。

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 12:1-8

Saamu 12

Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti ṣeminiti. Saamu ti Dafidi.

1Ràn wá lọ́wọ́, Olúwa, nítorí ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run kò sí mọ́;

Olóòtítọ́ tí pòórá kúrò láàrín àwọn ènìyàn.

2Olúkúlùkù ń parọ́ fún aládùúgbò rẹ̀;

ètè èké wọn ń sọ ẹ̀tàn.

3Olúwa kí ó gé ètè èké wọn

àti gbogbo ahọ́n ìfọ́nnu

4tí ó wí pé,

“Àwa ó borí pẹ̀lú ahọ́n wa;

àwa ní ètè wa: Ta ni ọ̀gá wa?”

5“Nítorí ìnilára àwọn aláìlágbára àti ìkérora àwọn aláìní,

Èmi yóò dìde nísinsin yìí” ni Olúwa wí.

“Èmi yóò dáàbò bò wọ́n lọ́wọ́ àwọn tí ń ṣe àrankàn wọn.”

6Ọ̀rọ̀ Olúwa sì jẹ aláìlábùkù,

gẹ́gẹ́ bí fàdákà tí a yọ́ nínú ìléru amọ̀,

tí a sọ di mímọ́ nígbà méje.

7Olúwa, ìwọ yóò pa wá mọ́

kí o sì gbà wá lọ́wọ́ àwọn ènìyàn wọ̀nyí títí láé.

8Àwọn ènìyàn búburú ń rin ìrìn fáàrí kiri

nígbà tí wọn ń bọ̀wọ̀ fún òsì láàrín àwọn ènìyàn.