箴言 28 – CCB & YCB

Chinese Contemporary Bible (Simplified)

箴言 28:1-28

1恶人未被追赶也逃窜,

义人坦然无惧如雄狮。

2国中有罪,君王常换;

国有哲士,长治久安。

3穷人28:3 穷人”有些抄本作“暴君”。欺压贫民,

如暴雨冲毁粮食。

4背弃律法的称赞恶人,

遵守律法的抗拒恶人。

5邪恶之人不明白公义,

寻求耶和华的全然明白。

6行为正直的穷人,

胜过行事邪僻的富人。

7遵守律法的是智慧之子,

与贪食者为伍令父蒙羞。

8人放高利贷牟利,

等于为扶贫者积财。

9人若不听从律法,

他的祷告也可憎。

10引诱正直人走邪道,

必掉进自己设的陷阱;

但纯全无过的人必承受福分。

11富人自以为有智慧,

却被明智的穷人看透。

12义人得胜,遍地欢腾;

恶人当道,人人躲藏。

13自掩其罪,必不亨通;

痛改前非,必蒙怜悯。

14敬畏上帝必蒙福,

顽固不化必遭祸。

15暴虐的君王辖制穷人,

如咆哮的狮、觅食的熊。

16昏庸的君王残暴不仁,

恨不义之财的享长寿。

17背负血债者必终生逃亡,

谁也不要帮他。

18纯全无过的必蒙拯救,

行为邪僻的转眼灭亡。

19勤奋耕耘,丰衣足食;

追求虚荣,穷困潦倒。

20忠信的人必大蒙祝福,

急于发财的难免受罚。

21徇私偏袒实不可取,

人却为一饼而枉法。

22贪婪的人急于发财,

却不知贫穷即将临到。

23责备人的至终比谄媚者更受爱戴。

24窃取父母之财而不知罪者与匪类无异。

25贪得无厌的人挑起纷争,

信靠耶和华的富足昌盛。

26愚人心中自以为是,

凭智慧行事的平安稳妥。

27周济穷人的一无所缺,

视而不见的多受咒诅。

28恶人当道,人人躲藏;

恶人灭亡,义人增多。

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Òwe 28:1-28

1Ènìyàn búburú ń sá bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹnìkan kò lé e

ṣùgbọ́n olódodo láyà bí i kìnnìún.

2Nígbà tí orílẹ̀-èdè bá ní orí kunkun, àwọn ọba rẹ̀ a máa pọ̀,

ṣùgbọ́n olóye àti onímọ̀ a máa pa òfin mọ́.

3Ọba tí ó ni àwọn tálákà lára

dàbí àgbàrá òjò tí ó ń gbá gbogbo ọ̀gbìn lọ.

4Àwọn tí ó kọ òfin sílẹ̀ a máa gbóríyìn fún ènìyàn búburú

ṣùgbọ́n àwọn tí ó pa òfin mọ́ kọjú ìjà sí ènìyàn búburú.

5Òye ìdájọ́ òdodo kò yé àwọn ẹni ibi

ṣùgbọ́n ó yé àwọn tí ń wá Olúwa dáradára.

6Ó sàn láti jẹ́ tálákà tí ìrìn rẹ̀ jẹ́ aláìlábùkù

ju ọlọ́rọ̀ tí ọ̀nà rẹ̀ rí pálapàla.

7Ẹni tí ó pa òfin mọ́ jẹ́ olóye ọmọ

ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá ẹ́ jẹgúdújẹrá kẹ́gbẹ́ dójútì baba rẹ̀.

8Ẹni tí ó mú ọrọ̀ rẹ̀ di púpọ̀ nípa èrè àjẹjù

ń kó jọ fún ẹlòmíràn, tí yóò ní àánú àwọn tálákà.

9Bí ẹnikẹ́ni bá kọ etí ikún sí òfin,

kódà àdúrà rẹ̀ jẹ́ ìríra.

10Ẹni tí ó mú olódodo rìn ọ̀nà búburú

yóò bọ́ sínú pàkúté ara rẹ̀

ṣùgbọ́n aláìlẹ́gàn yóò gba ogún rere.

11Ọlọ́rọ̀ ènìyàn le è gbọ́n lójú ara rẹ̀

ṣùgbọ́n tálákà tí ó ní òye rí ìdí, rẹ̀.

12Nígbà tí olódodo ń lékè ariwo ayọ̀ ta;

ṣùgbọ́n nígbà tí ènìyàn búburú gorí òye, àwọn ènìyàn a na pápá bora.

13Ẹni tí ó bo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ mọ́lẹ̀ kì yóò ṣe rere,

ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá jẹ́wọ́ tí ó sì kọ̀ wọ́n sílẹ̀ máa ń rí àánú gbà.

14Ìbùkún ni fún ènìyàn náà tí ó bẹ̀rù Ọlọ́run nígbà gbogbo

ṣùgbọ́n ẹni tí ó sé ọkàn rẹ̀ le bọ́ sínú wàhálà.

15Bí kìnnìún tí ń ké tàbí Beari tí ń halẹ̀

ni ènìyàn búburú tí ń jẹ ọba lórí àwọn aláìlágbára.

16Ọmọ-aládé tí ó ṣe aláìmòye púpọ̀ ní ń ṣe ìwà ìkà púpọ̀ pẹ̀lú,

ṣùgbọ́n èyí tí ó kórìíra ojúkòkòrò yóò mún ọjọ́ rẹ̀ pẹ́.

17Ẹni tí ọkàn rẹ̀ kò balẹ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ ìpànìyàn

yóò máa joró rẹ̀ títí ikú

má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni ràn án lọ́wọ́.

18Ẹni tí ń rìn déédéé ní yóò là,

ṣùgbọ́n ẹni tí ọ̀nà rẹ̀ jẹ́ àyídáyidà ni yóò ṣubú lójijì.

19Ẹni tí ó bá ro ilẹ̀ rẹ̀ yóò ní oúnjẹ lọ́pọ̀lọpọ̀

ṣùgbọ́n ẹni tí ń lé ohun asán yóò kún fún òsì.

20Olóòtítọ́ ènìyàn yóò rí ìbùkún gbà gan an

ṣùgbọ́n ẹni tí ojú ń kán láti di ọlọ́rọ̀ kì yóò lọ láìjìyà.

21Ojúsàájú ṣíṣe kò dára,

síbẹ̀ ènìyàn kan ń ṣẹ̀ nítorí òkèlè oúnjẹ kan.

22Ahun ń sáré àti là

kò sì funra pé òsì dúró de òun.

23Ẹni tí ó bá ènìyàn kan wí yóò rí ojúrere ni nígbẹ̀yìn

ju ẹni tí ó ní ètè ẹ̀tàn lọ.

24Ẹni tí ó ja baba tàbí ìyá rẹ̀ lólè

tí ó sì wí pé “Kì í ṣe ẹ̀ṣẹ̀”

irú kan ni òun àti ẹni tí ń pa ni run.

25Ọ̀kánjúwà ènìyàn a máa dá ìjà sílẹ̀,

ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá gbẹ́kẹ̀lé Olúwa yóò gbilẹ̀.

26Ẹni tí ó gbẹ́kẹ̀lé ara rẹ̀ jẹ́ aláìgbọ́n

ṣùgbọ́n ẹni tí ń rìn nínú ọgbọ́n wà láìléwu.

27Ẹni tí ó ń fi fún tálákà kì yóò ṣe aláìní ohunkóhun,

ṣùgbọ́n ẹni tí ó di ojú rẹ̀ sí wọn gba ọ̀pọ̀lọpọ̀ ègún.

28Nígbà tí ènìyàn búburú bá dórí ìjọba, àwọn ènìyàn a na pápá bora;

ṣùgbọ́n nígbà tí ènìyàn búburú bá ṣègbé,

àwọn olódodo ń gbilẹ̀ sí i.