箴言 20 – CCB & YCB

Chinese Contemporary Bible (Simplified)

箴言 20:1-30

1酒使人放肆,烈酒叫人吵闹。

因酒误事,实为不智。

2君王震怒如狮子咆哮,

触怒他的人自寻死路。

3避免纷争是光荣,

愚人个个爱争吵。

4懒惰人不按时耕种,

收获时必一无所得。

5人心的谋略如深水,

唯有哲士才能汲取。

6人都声称自己忠诚,

但谁能找到忠信者?

7义人行为正直,

他的后代也蒙福。

8王坐在宝座上审判,

他的眼目明察罪恶。

9谁敢说:“我心灵洁净,纯洁无罪?”

10缺斤少两、尺寸不足,

都为耶和华所憎恶。

11孩童的举动是否纯良,

都显明他的本性。

12能听的耳,能看的眼,

两者都为耶和华所造。

13不要贪睡,免得贫穷;

勤劳工作,粮食丰足。

14买主总说货物不好,

买走后又连连自夸。

15智慧之言胜过黄金和许多珠宝。

16谁为陌生人作保,就拿去谁的外衣;

谁为外族人作保,就要承担责任。

17骗来的饼觉得香甜,

最后却是满口泥沙。

18集思出良策,

征战靠智谋。

19嚼舌的人泄露秘密,

不可结交多嘴的人。

20咒骂父母的人,

他的生命20:20 生命”希伯来文是“灯”。必消逝在黑暗中。

21早年轻易得来之财,

最终不会成为祝福。

22不要说:“我要以恶报恶”,

要等候耶和华替你申冤。

23耶和华憎恶缺斤少两,

祂厌恶骗人的天平。

24人的脚步由耶和华所定,

人怎能知道自己的道路?

25人向主许愿要三思,

免得事后作茧自缚。

26明君必筛出恶人,

用石磙碾轧他们。

27心灵是耶和华的灯,

鉴察人的肺腑心肠。

28君王靠慈爱和忠信护佑,

他的王位因慈爱而稳固。

29力量是青年的荣耀,

白发是老人的尊荣。

30鞭伤能驱除罪恶,

责打能洁净人心。

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Òwe 20:1-30

1Ẹlẹ́yà ni ọtí wáìnì, aláriwo sì ní ọtí líle

ẹnikẹ́ni tí ó bá fi tànjẹ kò gbọ́n.

2Ìbẹ̀rù ọba dàbí kíké e kìnnìún;

ẹnikẹ́ni tí ó bá mú un bínú ba ayé ara rẹ̀ jẹ́.

3Iyì ni ó jẹ́ fún ènìyàn láti sá fún ìjà,

ṣùgbọ́n gbogbo aláìgbọ́n a máa tètè wá ìjà.

4Ọ̀lẹ kì í ṣiṣẹ́ oko nígbà tí ó yẹ,

nítorí náà ní àsìkò ìkórè, yóò wá kò sì ní rì nǹkan.

5Ète ọkàn ènìyàn dàbí omi jíjìn;

ṣùgbọ́n ènìyàn olóye á wá wọn jáde.

6Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni wọ́n máa ń sọ pe àwọn ní ìfẹ́ àìṣẹ̀tàn,

ṣùgbọ́n kò rọrùn láti rí ènìyàn olóòtítọ́.

7Olódodo ènìyàn a máa gbé ìgbé ayé àìlábùkù

ìbùkún ni fún àwọn ọmọ rẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀.

8Nígbà tí ọba bá jókòó sórí ìtẹ́ rẹ̀ láti ṣe ìdájọ́

yóò fẹ́ gbogbo ibi dànù pẹ̀lú ojú rẹ̀.

9Ta ni ó le è wí pé, “Mo ti ṣe ọkàn mi ní mímọ́,

mo mọ́, n kò sì lẹ́ṣẹ̀”?

10Ìwọ̀n èké àti òṣùwọ̀n ìrẹ́jẹ

Olúwa kórìíra méjèèjì.

11Kódà a mọ ọmọdé nípa iṣẹ́ rẹ̀

nípa pe bóyá iṣẹ́ rẹ mọ́ tàbí pé ó tọ̀nà.

12Etí tí ó ń gbọ́ àti ojú tí ó ń ríran

Olúwa ni ó dá méjèèjì.

13Má ṣe fẹ́ràn oorun, àìṣe bẹ́ẹ̀ ìwọ yóò di tálákà.

Ma ṣe sùn ìwọ yóò sì ní oúnjẹ láti tún fi tọrọ.

14“Kò dára, kò dára” ní ẹni tó ra ọjà máa ń wí

nígbà tí ó bá kúrò níbẹ̀ tán,

yóò máa yangàn bí òun tí ṣe rí rà sí.

15Wúrà wà, iyùn sì wà rẹpẹtẹ

ṣùgbọ́n, ahọ́n tí ń sọ ìmọ̀ gan an ni ọ̀ṣọ́ iyebíye.

16Gba abọ́ ẹni tí ó ṣe onídùúró fún àlejò;

mú un lọ́wọ́ bí ìbúra bí ó bá ṣe é fún obìnrin onírìnkurìn.

17Oúnjẹ tí a fi ọ̀nà èrú rí máa ń dùn lẹ́nu ènìyàn

ṣùgbọ́n, a yọrí sí ibi ẹnu tí ó kún fún erùpẹ̀.

18Pa ètè rẹ mọ́ nípa wíwá ìmọ̀ràn

bí o bá ń jagun, gba ìtọ́sọ́nà.

19Olófòófó a máa tú àṣírí

nítorí náà yẹra fún ènìyàn tí ń rojọ́ púpọ̀.

20Bí ènìyàn kan bá ṣépè fún baba tàbí ìyá rẹ̀,

ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ ni a ó pa kú nínú òkùnkùn biribiri.

21Ogún tí a kójọ kíákíá ní ìbẹ̀rẹ̀

kì yóò ní ìbùkún ní ìgbẹ̀yìn gbẹ́yín.

22Má ṣe wí pé, “N ó ṣẹ̀san àṣìṣe rẹ yìí fún ọ”

Dúró de Olúwa yóò sì gbà ọ́ là.

23Olúwa kórìíra òdínwọ̀n èké.

Òṣùwọ̀n ìrẹ́jẹ kò sì tẹ́ ẹ lọ́rùn.

24Olúwa ni ó ń ṣe olùdarí ìgbésẹ̀ ènìyàn

Báwo wá ni òye gbogbo ọ̀nà ènìyàn ṣe le yé ni?

25Ìdẹ̀kùn ni fún ènìyàn láti ṣe ìlérí kíákíá

nígbà tí ó bá sì yá kí ó máa ro ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ wò.

26Ọlọ́gbọ́n ọba tú ènìyàn búburú ká;

Ó sì fi òòlọ ìpakà lọ̀ wọ́n.

27Àtùpà Olúwa ń ṣe àwárí ẹ̀mí ènìyàn

a máa ṣàwárí ibi ìkọ̀kọ̀ inú.

28Ìfẹ́ àti òdodo pa ọba mọ́,

nípa ìfẹ́, ìtẹ́ rẹ̀ wà láìléwu.

29Ògo àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin ni agbára wọn,

ewú orí ni iyì arúgbó.

30Ìgbájú ìgbámú àti ìfarapa máa ń mú ibi lọ,

pàṣán sì máa ń ṣe àfọ̀mọ́ ibi ìkọ̀kọ̀ inú.