弥迦书 3 – CCB & YCB

Chinese Contemporary Bible (Simplified)

弥迦书 3:1-12

斥责以色列的领袖

1我说:“雅各的首领,以色列家的统治者啊!

你们要听!

难道你们不知正义吗?

2你们憎恶良善,

喜爱邪恶,

剥下我百姓的皮,

从他们的骨头上剔肉。

3你们吃我百姓的肉,

剥我百姓的皮,

打碎他们的骨头,

把他们切成块,

如同下在锅里、放进釜中的肉。

4你们遭难的时候,

向耶和华呼求,

祂必不应允你们。

因你们的恶行,

祂必掩面不顾你们。”

5耶和华说:

“使我的子民步入歧途的先知啊,

你们向供养你们的人报平安,

出言攻击那不供养你们的人。

6因此,黑夜必笼罩你们,

使你们看不见异象;

幽暗必临到你们,

使你们无法占卜。

太阳要因你们而沉落,

白昼变为黑夜。

7假先见必抱愧,

占卜者必蒙羞。

因得不到上帝的答复,

你们必羞愧地捂着脸。”

8至于我,

因有耶和华的灵,

我充满权能、正义和力量,

能向雅各宣告他的过犯,

以色列宣告他的罪恶。

9雅各家的首领,以色列家的统治者啊,

你们要听!

你们厌恶正义,颠倒是非;

10以血腥建立锡安

以罪恶建造耶路撒冷

11城里的首领为贪赃而枉法,

祭司为银子而施教,

先知为钱财而占卜。

他们却宣称倚靠耶和华,说:

“耶和华不是在我们当中吗?

灾祸不会临到我们。”

12所以,因你们的缘故,

锡安必像田地被耕犁,

耶路撒冷必沦为废墟,

圣殿山必成为荒林之冈。

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Mika 3:1-12

Bíbá àwọn olórí àti àwọn wòlíì wí

1Nígbà náà, ni mo wí pé,

“Ẹ gbọ́, ẹ̀yin olórí Jakọbu,

ẹ̀yin alákòóso ilé Israẹli.

Ǹjẹ́ ẹ̀yin kò ha ni í gba òdodo bí.

2Ẹ̀yin tí ó kórìíra ìre, tí ẹ sì fẹ́ràn ibi;

Ẹ̀yin tí ẹ fa awọ ẹran-ara àwọn ènìyàn mi ya kúrò lára wọn

àti ẹran-ara wọn kúrò ní egungun wọn;

3Àwọn tí ó jẹ ẹran-ara àwọn ènìyàn mi,

wọn sì bọ́ awọ ara wọn kúrò lára wọn.

Wọ́n sì fọ́ egungun wọn sí wẹ́wẹ́;

Wọn sì gé e sí wẹ́wẹ́ bí ẹran inú ìkòkò,

bí ẹran inú agbada?”

4Nígbà náà ni wọn yóò kígbe sí Olúwa,

Ṣùgbọ́n òun kì yóò dá wọn lóhùn.

Ní àkókò náà ni òun yóò fi ojú rẹ̀ pamọ́ kúrò lọ́dọ̀ wọn,

nítorí ibi tí wọ́n ti ṣe.

5Báyìí ni Olúwa wí:

“Ní ti àwọn Wòlíì

tí ń ṣi àwọn ènìyàn mi lọ́nà,

tí ẹnìkan bá fún wọn ní oúnjẹ,

wọn yóò kéde àlàáfíà;

Ṣùgbọ́n tí kò bá fi nǹkan sí wọn ní ẹnu,

wọn yóò múra ogun sí i.

6Nítorí náà òru yóò wá sórí yín,

tí ẹ̀yin kì yóò sì rí ìran kankan,

òkùnkùn yóò sì kùn fún yín,

tí ẹ̀yin kì yóò sì lè sọtẹ́lẹ̀

Oòrùn yóò sì wọ lórí àwọn wòlíì

ọjọ́ yóò sì ṣókùnkùn lórí wọn.

7Ojú yóò sì ti àwọn Wòlíì

àwọn alásọtẹ́lẹ̀ pẹ̀lú yóò sì gba ìtìjú.

Gbogbo wọn ni yóò bo ojú wọn,

nítorí kò sí ìdáhùn láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run.”

8Ṣùgbọ́n ní tèmi,

èmi kún fún agbára pẹ̀lú ẹ̀mí Olúwa,

láti sọ ìré-òfin-kọjá Jakọbu fún un,

àti láti sọ ẹ̀ṣẹ̀ Israẹli fún un.

9Gbọ́ ẹ̀yin olórí ilé Jakọbu,

àti ẹ̀yin alákòóso ilé Israẹli,

tí ó kórìíra òdodo

tí ó sì yí òtítọ́ padà;

10Tí ó kọ́ Sioni pẹ̀lú ìtàjẹ̀ sílẹ̀,

àti Jerusalẹmu pẹ̀lú ìwà búburú.

11Àwọn olórí rẹ̀ ń ṣe ìdájọ́ nítorí àbẹ̀tẹ́lẹ̀,

àwọn àlùfáà rẹ̀ sì ń kọ́ni nítorí owó ọ̀yà

àwọn wòlíì rẹ̀ pẹ̀lú sì ń sọtẹ́lẹ̀ nítorí owó.

Síbẹ̀, wọn gbẹ́kẹ̀lé Olúwa, wọ́n sì wí pé,

“Nítòótọ́, Olúwa wà pẹ̀lú wa!

Ibi kan kì yóò bá wa.”

12Nítorí náà, nítorí tiyín,

ni a ó ṣe ro Sioni bí oko,

Jerusalẹmu yóò sì di ebè

àti òkè tẹmpili bí i ibi gíga igbó.