帖撒罗尼迦后书 3 – CCB & YCB

Chinese Contemporary Bible (Simplified)

帖撒罗尼迦后书 3:1-18

请求代祷

1弟兄姊妹,最后我还要请你们为我们祷告,好使主的道像在你们那里一样迅速传开,受到尊崇, 2并使我们能避开那些邪恶的人,因为不是人人都有信心。

3主是信实的,祂必使你们刚强,保护你们脱离那恶者。 4我们靠着主深信你们现在遵行了我们的吩咐,而且以后还会继续遵行。

5愿主引导你们的心领悟上帝的爱和基督的坚忍。

不可游手好闲

6弟兄姊妹,现在我们奉主耶稣基督的名吩咐你们,要远离那些游手好闲、不遵守我们教导的信徒。 7你们自己知道应该怎样效法我们,因为我们在你们那里的时候,并没有懒懒散散, 8也没有白吃谁的饭,而是昼夜辛勤工作,免得成为你们任何人的负担。 9我们并不是没有权利接受供应,而是要给你们树立学习的榜样。 10我们在你们那里的时候,曾吩咐过你们:不肯工作的人没有资格吃饭。 11我们听说在你们当中有些人游手好闲,无所事事,却专管闲事。 12我们奉主耶稣基督的名吩咐并劝诫这些人要安分守己,自食其力。

13弟兄姊妹,你们要坚持行善,不要灰心。 14如果有人不听从这信上的教导,要注意提防他,不要和他来往,好使他羞愧。 15只是不可把他当作仇人,要像对待弟兄姊妹一样劝诫他。

问候

16愿平安之主随时随地亲自赐你们平安!愿主与你们同在! 17我保罗在这里亲笔问候你们,这是我的笔迹,我所有的信都以此为记号。

18愿我们主耶稣基督的恩典与你们众人同在!

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

2 Tẹsalonika 3:1-18

Ẹ̀bẹ̀ àdúrà

13.1: 1Tẹ 5.25; 1.8.Ní àkótán, ará, ẹ máa gbàdúrà fún wa, kí ọ̀rọ̀ Olúwa lè máa tàn káàkiri, kí ó sì jẹ́ èyí tí a bu ọlá fún, gẹ́gẹ́ bí ó ti rí ní ọ̀dọ̀ yín. 23.2: Ro 15.31.Kí ẹ sì máa gbàdúrà fún wa kí a lè bọ́ lọ́wọ́ àwọn ìkà àti àwọn ènìyàn búburú, nítorí pé kì í ṣe gbogbo ènìyàn ló ní ìgbàgbọ́. 33.3: 1Kọ 1.9; 1Tẹ 5.24.Ṣùgbọ́n olódodo ni Olúwa, ẹni tí yóò fi ẹsẹ̀ yín múlẹ̀, tí yóò sì pa yín mọ́ kúrò nínú ibi. 4Àwa sì ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú Olúwa ní ti ohun tí ẹ ń ṣe, àti pé àwọn nǹkan wọ̀n-ọn-nì tí a pàṣẹ fún un yín ni ẹ̀yin ń ṣe. 5Kí Olúwa máa tọ́ ọkàn yín ṣọ́nà sí ìfẹ́ Ọlọ́run àti sínú sùúrù Kristi.

Ìkìlọ̀ ní ṣíṣe ìmẹ́lẹ́

63.6: 1Kọ 5.4,5,11; 1Tẹ 5.14.Ní orúkọ Jesu Kristi Olúwa wa, àwa pàṣẹ fún un yín ará, pé kí ẹ yẹra fún gbogbo àwọn arákùnrin yín tí ń ṣe ìmẹ́lẹ́, tí kò sì gbé ní ìbámu pẹ̀lú ẹ̀kọ́ tí ẹ gbà ní ọ̀dọ̀ wa. 73.7: 1Tẹ 1.6,9.Nítorí ẹ̀yin náà mọ̀ bí ó ṣe yẹ kí ẹ máa fi ara wé wa. Àwa kì í ṣe ìmẹ́lẹ́ nígbà tí a wà ní ọ̀dọ̀ yín. 83.8: 1Tẹ 2.9; Ap 18.3; Ef 4.28.Bẹ́ẹ̀ ni àwa kò sì jẹ oúnjẹ ẹnikẹ́ni lọ́fẹ̀ẹ́. Ṣùgbọ́n dípò bẹ́ẹ̀, àwa ń ṣiṣẹ́ tọ̀sán tòru kí a má ba à di àjàgà sí ẹnikẹ́ni nínú yín lọ́rùn. 93.9: 2Tẹ 3.7.Àwa ń ṣe nǹkan wọ̀nyí, kì í ṣe nítorí pé àwa kò ní ẹ̀tọ́ láti béèrè fún un, ṣùgbọ́n àwa ń fi ara wa ṣe àpẹẹrẹ tí ẹ ó tẹ̀lé. 103.10: 1Tẹ 4.11.Nítorí nígbà tí àwa wà lọ́dọ̀ yín, a ṣe àwọn òfin wọ̀nyí fún un yín pé, “Bí ẹnikẹ́ni kò bá fẹ́ ṣiṣẹ́, kí ó má ṣe jẹun.”

113.11: 2Tẹ 3.6.A gbọ́ pé àwọn kan wà láàrín yín tí wọn jẹ́ ìmẹ́lẹ́. Wọ́n jẹ́ atọjúlékiri. 123.12: 1Tẹ 4.1,11.Ǹjẹ́ irú àwọn ẹni bẹ́ẹ̀ ni àwa ń pàṣẹ fún, tí a sì ń rọ̀ nínú Jesu Kristi Olúwa pé kí wọn ó máa ṣiṣẹ́ fún oúnjẹ tí wọ́n ń jẹ. 133.13: Ga 6.9.Ṣùgbọ́n ní tiyín ará, ẹ má ṣe jẹ́ kí agara dá yín ní rere ṣíṣe.

14Bí ẹnikẹ́ni kò bá sì pa òfin wa nínú lẹ́tà yìí mọ́, ẹ ṣààmì sí ẹni náà. Ẹ má ṣe bá a kẹ́gbẹ́ kí ojú bà á le tì í. 15Síbẹ̀, ẹ má ṣe kà á sí ọ̀tá, ṣùgbọ́n ẹ máa kìlọ̀ fún un gẹ́gẹ́ bí arákùnrin yín.

Ìkíni ìkẹyìn

163.16: Ru 2.4.Ǹjẹ́ kí Olúwa àlàáfíà, fúnrarẹ̀ máa fún yín ní àlàáfíà nígbà gbogbo. Kí Olúwa kí ó wà pẹ̀lú gbogbo yín.

173.17: 1Kọ 16.21.Èmi Paulu fi ọwọ́ ara mi kọ lẹ́tà ìkíni yìí, èyí ṣe ààmì ìdámọ̀ nínú gbogbo lẹ́tà. Bí mo ṣe máa ń kọ̀wé nìyìí.

183.18: Ro 16.20; 1Tẹ 5.28.Kí oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Olúwa wa wà pẹ̀lú yín.