启示录 17 – CCB & YCB

Chinese Contemporary Bible (Simplified)

启示录 17:1-18

大淫妇的下场

1拿着七碗的七位天使中有一位前来对我说:“你过来!我要让你看那坐在众水之上的大淫妇将要遭受的刑罚。 2地上的君王与她行淫,地上其他人也因喝了她淫乱的酒而酩酊大醉。”

3那时,我被圣灵感动,被天使带到旷野,在那里见到一个妇人骑着一只朱红色的怪兽。怪兽有七头十角,浑身写满亵渎上帝的名号。 4那妇人身穿紫色和朱红色的袍子,用黄金、宝石及珍珠装扮自己。她手中拿着金杯,里面盛满了她淫乱的污秽、可憎之物。 5在她额上还写了一个神秘的名号:“大巴比伦——地上淫妇及可憎事物之母”。 6我又见她醉了,因她喝了众圣徒的血,就是为耶稣做见证之人的血。

我看见她,非常惊奇。 7天使对我说:“你为什么这样惊奇呢?我要将这妇人和她骑的七头十角怪兽的奥秘告诉你。 8你看见的这怪兽以前出现过,现今没有出现,将来要从无底坑上来,然后走向灭亡。那些住在地上、自创世以来名字没有记在生命册上的人,都因见到这只从前出现过、现今没有出现、将来会再出现的怪兽而感到惊奇。 9这里需要智慧才能明白,它的七个头代表那妇人坐镇的七座山,又代表七个王。 10其中五个已经衰亡,一个还在,另外一个还未来到,他来后只能短暂存留。 11那从前出现过、现今没有出现的怪兽是第八个王,他是七个王之一,也要走向灭亡。 12你看见的那十个角象征另外十个还没有得势的王,他们将取得王权和那怪兽一同统治短暂的一段时期。 13他们一致同意把自己所有的能力和权柄交给那怪兽。 14他们将与羔羊交战,但羔羊必胜过他们,因为羔羊是万主之主,万王之王。那些跟随羔羊的是被呼召、蒙拣选、忠心耿耿的人。”

15天使又对我说:“你看见的那淫妇所坐的众水象征来自各民族、各国家、各语言族群的人。 16怪兽和它头上的十角必憎恨那淫妇,使她赤身露体、景况凄凉。它们要吃她的肉,最后用火将她烧尽。 17因为上帝使众王定意这样做,好完成祂的旨意。他们便同心将政权交给那怪兽,直到上帝的话得到实现。 18你看见的那妇人就是那掌管世上众王的大城。”

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Ìfihàn 17:1-18

Obìnrin àti ẹranko

117.1: Jr 51.13.Ọ̀kan nínú àwọn angẹli méje náà tí ó ní ìgò méje wọ̀n-ọn-nì sì wá, ó sì ba mi sọ̀rọ̀ wí pé, “Wá níhìn-ín; èmi ó sì fi ìdájọ́ àgbèrè ńlá ní tí ó jókòó lórí omi púpọ̀ han ọ: 217.2: Isa 23.17; Jr 25.15-16.Ẹni tí àwọn ọba ayé bá ṣe àgbèrè, tí a sì fi ọtí wáìnì àgbèrè rẹ̀ pa àwọn tí ń gbé inú ayé.”

3Ó sì gbé mi nínú ẹ̀mí lọ sí aginjù: mo sì rí obìnrin kan ó jókòó lórí ẹranko aláwọ̀ òdòdó kan tí ó kún fún orúkọ ọ̀rọ̀-òdì, ó ní orí méje àti ìwo mẹ́wàá. 417.4: Jr 51.7.A sì fi aṣọ elése àlùkò àti aṣọ òdòdó wọ obìnrin náà, a sì fi wúrà àti òkúta iyebíye àti perli ṣe é ní ọ̀ṣọ́, ó ní ago wúrà kan ní ọwọ́ rẹ̀, tí ó kún fún ìríra àti fún ẹ̀gbin àgbèrè rẹ̀; 5àti níwájú rẹ̀ ni orúkọ kan tí a kọ:

ohun ìjìnlẹ̀ babeli ńlá

ìyá àwọn panṣágà

àti àwọn ohun ìríra ayé.

6Mo sì rí obìnrin náà mu ẹ̀jẹ̀ àwọn ènìyàn mímọ́, àti ẹ̀jẹ̀ àwọn ajẹ́rìí ikú Jesu ní àmuyó.

Nígbà tí mo sì rí i, ẹnu yà mi gidigidi. 7Angẹli sì wí fún mi pé, “Nítorí kí ni ẹnu ṣe yà ọ́? Èmi ó sọ ti ìjìnlẹ̀ obìnrin náà fún ọ, àti ti ẹranko tí ó gùn, ti ó ní orí méje àti ìwo mẹ́wàá. 817.8: Da 7.3; If 3.5.Ẹranko tí ìwọ ri nì, o ti wà, kò sì ṣí mọ́: Yóò sì ti inú ọ̀gbun gòkè wá, yóò sì lọ sínú ìparun rẹ. Àwọn olùgbé ayé ti a kọ orúkọ wọn sínú ìwé iye láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé, nígbà tí wọn ń wò ẹranko tí o ti wà, tí kò sì ṣí mọ́, tí ó sì ń bọ̀ wá, ẹnu si ya wọn.

9“Níhìn-ín ni ìtumọ̀ tí o ní ọgbọ́n wà. Orí méje ni òkè ńlá méje ni, lórí èyí tí obìnrin náà jókòó. 10Ọba méje sì ní wọn: àwọn márùn-ún ṣubú, ọ̀kan ń bẹ, ọ̀kan ìyókù kò sì tí ì dé; nígbà tí ó bá sì dé, yóò dúró fún ìgbà kúkúrú. 11Ẹranko tí ó sì ti wà, tí kò sì ṣí, òun náà sì ni ẹ̀kẹjọ, ó sì ti inú àwọn méje náà wá, ó sì lọ sí ìparun.

1217.12: Da 7.20-24.“Ìwo mẹ́wàá tí ìwọ sì rí ni ọba mẹ́wàá ni wọn, tí wọn kò ì ti gba ìjọba; ṣùgbọ́n wọn gba àṣẹ bí ọba pẹ̀lú ẹranko náà fún wákàtí kan. 13Àwọn wọ̀nyí ní inú kan, wọ́n yóò sì fi agbára àti ọlá wọn fún ẹranko náà. 1417.14: Da 2.47.Àwọn wọ̀nyí ni yóò si máa bá Ọ̀dọ́-Àgùntàn jagun, Ọ̀dọ́-Àgùntàn náà yóò sì ṣẹ́gun wọn: nítorí òun ni Olúwa àwọn Olúwa, àti ọba àwọn ọba: Àwọn tí ó sì wà pẹ̀lú rẹ̀, tí a pè, tí a yàn, tí wọ́n sì jẹ́ olóòtítọ́ yóò sì ṣẹ́gun pẹ̀lú.”

15Ó sì wí fún mi pé, “Àwọn omi tí ìwọ ti rí ni, níbi tí àgbèrè náà jókòó, àwọn ènìyàn àti ẹ̀yà àti orílẹ̀ àti onírúurú èdè ni wọ́n. 16Àti ìwo mẹ́wàá tí ìwọ rí, àti ẹranko náà, àwọn wọ̀nyí ni yóò kórìíra àgbèrè náà, wọn ó sì sọ ọ́ di ahoro àti ẹni ìhòhò, wọn ó sì jẹ ẹran-ara rẹ̀, wọn ó sì fi iná sun ún pátápátá. 17Nítorí Ọlọ́run ti fi sínú ọkàn wọn láti mú ìfẹ́ rẹ̀ ṣẹ, láti ní inú kan, àti láti fi ìjọba wọn fún ẹranko náà, títí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run yóò fi ṣẹ 18Obìnrin tí ìwọ rí ní ìlú ńlá ni, tí ń jẹ ọba lórí àwọn ọba ilẹ̀ ayé.”