利未记 24 – CCB & YCB

Chinese Contemporary Bible (Simplified)

利未记 24:1-23

灯和供饼的条例

1耶和华对摩西说: 2“你要吩咐以色列人给你拿来纯橄榄油,作点灯之用,使灯常常亮着。 3在会幕遮掩约柜的幔子外,亚伦要负责照看灯,使灯从晚上到早晨一直亮着。这是你们世世代代都要遵守的律例。 4亚伦要常常照看这些放在纯金灯台上的灯。

5“你要用细面粉烤十二个饼,每个饼用两公斤细面粉。 6你要把饼摆成两行放在耶和华面前的纯金桌子上,每行六个, 7每行饼上放一些纯乳香,象征这些饼是献给耶和华的火祭。 8每逢安息日,要定期把饼摆在耶和华面前。这是以色列人要永远遵守的约。 9这些饼要归亚伦及其子孙。他们要在圣洁之处吃,因为在献给耶和华的火祭中,这是至圣之物,要永远归祭司所有。”

处死亵渎圣名者

10有一个人,母亲是以色列人,父亲是埃及人,在营中与一个以色列人打起架来。 11他竟说咒诅的话,亵渎了上帝的名,他们把他带到摩西那里。原来他母亲叫示罗密,是支派示伯利的女儿。 12他们把他关押起来,等候耶和华的指示。 13耶和华对摩西说: 14“把那亵渎圣名的人带到营外,叫听见的人把手放在他头上,然后全体会众要用石头打死他。 15你要告诉以色列人,谁咒诅上帝,谁就要承担自己的罪。 16凡亵渎耶和华圣名的,必须被处死,全体会众要用石头打死他。不论是外族人还是以色列人,凡亵渎圣名的,都必须被处死。 17凡杀人的,必须被处死。 18打死别人牲畜的,必须赔偿牲畜,以命还命。 19有人伤害别人,也要同样对待他, 20要以眼还眼,以牙还牙。他怎样伤害别人,也要怎样伤害他。 21打死别人牲畜的,必须赔偿牲畜;杀人的,必须偿命。 22不论是以色列人还是外族人,都要遵守这些律法。我是你们的上帝耶和华。” 23于是,摩西把这些话告诉以色列人,他们就按照耶和华对摩西的吩咐,把那亵渎圣名的人带到营外,用石头打死了。

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Lefitiku 24:1-23

Òróró òun àkàrà tí a tẹ́ síwájú Olúwa

124.1-4: El 27.20,21.Olúwa sọ fún Mose pé 2“Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli láti mú òróró tí ó mọ́ tí a fún láti ara olifi wá láti fi tan iná, kí fìtílà lè máa jò láì kú. 3Lẹ́yìn aṣọ ìkélé ti ibi àpótí ẹ̀rí tí ó wà ní inú àgọ́ ìpàdé, ni kí Aaroni ti tan iná náà níwájú Olúwa, láti ìrọ̀lẹ́ di àárọ̀ lójoojúmọ́. Èyí yóò jẹ́ ìlànà ayérayé fún àwọn ìran tí ń bọ̀. 4Àwọn Àtùpà tí wọ́n wà lórí ojúlówó ọ̀pá fìtílà tí a fi wúrà ṣe níwájú Olúwa ni kí ó máa jó lójoojúmọ́.

524.5-9: Ek 25.30; 39.36; 40.23; Mt 12.4; Mk 2.26; Lk 6.4.“Mú ìyẹ̀fun dáradára, kí o sì ṣe ìṣù àkàrà méjìlá, kí o lo ìdá méjì nínú mẹ́wàá òṣùwọ̀n efa (èyí jẹ́ lítà mẹ́rin ààbọ̀) fún ìṣù kọ̀ọ̀kan. 6Tò wọ́n sí ọ̀nà ìlà méjì, mẹ́fàmẹ́fà ní ìlà kọ̀ọ̀kan lórí tábìlì tí a fi ojúlówó wúrà bọ̀. Èyí tí ó wà níwájú Olúwa. 7Ẹ fi ojúlówó tùràrí sí ọnà kọ̀ọ̀kan, gẹ́gẹ́ bí ìpín ìrántí láti dípò àkàrà, àti láti jẹ ẹbọ sísun sí Olúwa. 8Àkàrà yìí ni kí ẹ gbé wá síwájú Olúwa nígbàkúgbà, lọ́ṣọ̀ọ̀ṣẹ̀, nítorí tí àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ bí májẹ̀mú ayérayé. 9Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ ló ni í. Wọ́n gbọdọ̀ jẹ ẹ́ ní ibi mímọ́ torí pé ó jẹ́ ipa tí ó mọ́ jùlọ ti ìpín wọn ojoojúmọ́ nínú ọrẹ tí a fi iná ṣe sí Olúwa.”

Ìṣọ̀rọ̀-òdì àti ìjìyà rẹ̀

10Ọmọkùnrin kan wà tí ìyá rẹ̀ jẹ́ ọmọ Israẹli baba rẹ̀ sì jẹ́ ará Ejibiti. Ó jáde lọ láàrín àwọn ọmọ Israẹli, ìjà sì ṣẹlẹ̀ nínú àgọ́ láàrín òun àti ọmọ Israẹli kan. 11Ọmọkùnrin arábìnrin Israẹli náà sọ̀rọ̀-òdì sí orúkọ Olúwa pẹ̀lú èpè: Wọ́n sì mú un tọ Mose wá. (Orúkọ ìyá rẹ̀ ní Ṣelomiti, ọmọbìnrin Debiri, ti ẹ̀yà Dani). 12Wọ́n fi í sínú túbú kí Olúwa to sọ ohun tí wọn yóò ṣe fún wọn.

13Olúwa sì sọ fún Mose pé: 14“Mú asọ̀rọ̀-òdì náà jáde wá sẹ́yìn àgọ́, kí gbogbo àwọn tí ó gbọ́ pé ó ṣépè gbé ọwọ́ wọn lórí ọkùnrin náà láti fihàn pé ó jẹ̀bi. Lẹ́yìn náà ni kí gbogbo àpéjọpọ̀, sọ ọ́ ní òkúta pa. 15Sọ fún àwọn ará Israẹli pé: ‘Bí ẹnikẹ́ni bá ṣépè lé Ọlọ́run rẹ̀, yóò jìyà ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀. 16Ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ̀rọ̀-òdì sí orúkọ Olúwa ni kí ẹ pa, kí gbogbo àpéjọpọ̀ sọ ọ́ ní òkúta pa, yálà àlejò ni tàbí ọmọ bíbí Israẹli, bí ó bá ti sọ̀rọ̀-òdì sí orúkọ Olúwa, pípa ni kí ẹ pa á.

17“ ‘Ẹni tí ó bá gba ẹ̀mí ènìyàn pípa ni kí ẹ pa á. 18Ẹni tí ó bá gba ẹ̀mí ẹran ọ̀sìn ẹlòmíràn, kí ó dá a padà—ẹ̀mí dípò ẹ̀mí. 1924.19,20: El 21.23-25; De 19.21; Mt 5.38.Bí ẹnìkan bá pa ẹnìkejì rẹ̀ lára: ohunkóhun tí ó ṣe ni kí ẹ ṣe sí i. 20Ẹ̀yà fún ẹ̀yà, ojú fún ojú, eyín fún eyín; bí òun ti ṣe àbùkù sí ara ènìyàn, bẹ́ẹ̀ ni kí a ṣe sí i. 21Ẹni tí ó bá sì lu ẹran pa, kí ó sán an padà; ẹni tí ó bá sì lu ènìyàn pa, a ó pa á. 2224.22: El 12.19; Nu 9.14; 15.15,16,29.Òfin kan náà ló wà fún àlejò àti fún ọmọ Israẹli. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’ ”

23Nígbà náà ni Mose sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì mú asọ̀rọ̀-òdì náà lọ sí ẹ̀yìn àgọ́: wọ́n sì sọ ọ́ ní òkúta pa. Àwọn ọmọ Israẹli sì ṣe ohun tí Olúwa pàṣẹ fún Mose.