Иеремия 45 – CARST & YCB

Священное Писание (Восточный перевод), версия для Таджикистана

Иеремия 45:1-5

Послание Баруху

1Вот что сказал пророк Иеремия Баруху, сыну Нерии, в четвёртом году правления иудейского царя Иоакима, сына Иосии (в 605 г. до н. э.), после того, как Барух записал в свиток слова, которые продиктовал ему Иеремия45:1 См. 36:1-4, 32.:

2– Так говорит Вечный, Бог Исроила, тебе, Барух: 3«Ты говорил: „Горе мне! Вечный прибавил скорбь к моим мукам; я устал от стонов и не нахожу покоя“».

4Скажи ему: «Так говорит Вечный: Я разрушу то, что построил, и искореню то, что насадил, во всей этой стране. 5Тебе ли искать для себя чудес? Не ищи. Я насылаю беду на всякую плоть, – возвещает Вечный, – но куда бы ты ни отправился, Я спасу тебя».

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Jeremiah 45:1-5

Ìlérí Ọlọ́run fún Baruku

1Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Jeremiah wòlíì sọ fún Baruku ọmọ Neriah ní ọdún kẹrin ti Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda. Lẹ́yìn tí Baruku ti kọ sínú ìwé kíká àwọn ọ̀rọ̀ tí Jeremiah ti ń sọ: 2“Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ fún ọ, Baruku: 3Ìwọ wí pé, ‘Ègbé ni fún mi! Olúwa ti fi ìbànújẹ́ kún ìrora mi; Àárẹ̀ mú mi nínú ẹ̀dùn mi, èmi kò sì rí ìsinmi.’ ” 4Olúwa wí pé sọ èyí fún un, “Èyí ni Ọlọ́run sọ: ‘Èyí tí èmi ti kọ́ ni èmi yóò wò lulẹ̀, àti èyí tí èmi ti gbìn ni èmi yóò fàtu, àní ní orí gbogbo ilẹ̀. 5Ṣé ìwọ sì ń wá ohun títóbi fún ara rẹ? Nítorí náà, má ṣe wá wọn. Èmi yóò mú ibi wá sí orí àwọn ènìyàn gbogbo ni Olúwa wí, ṣùgbọ́n níbikíbi tí ìwọ bá lọ ni èmi yóò jẹ́ kí o sá àsálà pẹ̀lú ẹ̀mí rẹ.’ ”