Lovsang til Gud
1Til den tid vil du sige:
„Jeg takker dig, Herre.
Du blev vred på mig,
men din vrede forsvandt,
og du trøstede mig.
2Du er min Frelser,
jeg stoler på dig.
Jeg frygter ikke,
for du giver mig styrke.
Jeg lovsynger dig,
for du frelste mig.”
3Med glæde skal I øse vand
fra frelsens kildevæld.
4Til den tid skal I synge:
„Tak Herren, og påkald hans navn.
Alle folk skal høre, hvad han har gjort.
De skal få at vide, hvor mægtig han er.
5Syng for Herren!
Han har gjort store undere,
som hele verden bør høre om.
6Råb af fryd, I, som bor på Zion.
Israels hellige Gud er stor iblandt jer.”
Orin ìyìn
1Ní ọjọ́ náà ni ìwọ ó wí pé:
“Èmi ó yìn ọ́, Olúwa.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ò ti bínú sí mi
ìbínú rẹ ti yí kúrò níbẹ̀
ìwọ sì ti tù mí nínú.
2Nítòótọ́ Ọlọ́run ni ìgbàlà mi,
èmi yóò gbẹ́kẹ̀lé e èmi kì yóò bẹ̀rù.
Olúwa, Olúwa náà ni agbára à mi àti orin ìn mi,
òun ti di ìgbàlà mi.”
3Pẹ̀lú ayọ̀ ni ìwọ yóò máa pọn omi
láti inú kànga ìgbàlà.
4Ní ọjọ́ náà, ìwọ yóò wí pé:
“Fi ọpẹ́ fún Olúwa, ké pe orúkọ rẹ̀,
Jẹ́ kí ó di mí mọ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,
ohun tí ó ti ṣe
kí o sì kéde pé a ti gbé
orúkọ rẹ̀ ga.
5Kọ orin sí Olúwa, nítorí ó ti ṣe ohun tí ó lógo,
jẹ́ kí èyí di mí mọ̀ fún gbogbo ayé.
6Kígbe sókè kí o sì kọrin fún ayọ̀, ẹ̀yin ènìyàn Sioni,
nítorí títóbi ni ẹni mímọ́ kan ṣoṣo
ti Israẹli láàrín yín.”