Ayeyi Nnwom
1Saa da no, wobɛka se:
“Mɛkamfo wo, Awurade!
Ɛwɔ mu wo bo fuw me de,
nanso afei wʼabufuw ano adwo.
Na woakyekye me werɛ.
2Nokware, Onyankopɔn ne mʼagyenkwa;
mede me ho bɛto no so, na merensuro.
Awurade, Awurade ne mʼahoɔden ne me dwom;
na wabɛyɛ me nkwagye.”
3Wode anigye bɛsaw nsu
afi nkwagye mmura mu.
4Saa da no wobɛka se,
“Da Awurade ase, bɔ ne din
ma amanaman nhu nea wayɛ,
na pae mu ka se wɔama ne din so.
5To dwom ma Awurade, efisɛ, wayɛ nea ɛwɔ anuonyam bebree.
Da eyi adi kyerɛ wiase nyinaa.
6Momma mo nne so nto dwom anigye so
mo a mowɔ Sion,
efisɛ Israel Kronkronni a ɔte mo mu no yɛ ɔkɛse.”
Orin ìyìn
1Ní ọjọ́ náà ni ìwọ ó wí pé:
“Èmi ó yìn ọ́, Olúwa.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ò ti bínú sí mi
ìbínú rẹ ti yí kúrò níbẹ̀
ìwọ sì ti tù mí nínú.
2Nítòótọ́ Ọlọ́run ni ìgbàlà mi,
èmi yóò gbẹ́kẹ̀lé e èmi kì yóò bẹ̀rù.
Olúwa, Olúwa náà ni agbára à mi àti orin ìn mi,
òun ti di ìgbàlà mi.”
3Pẹ̀lú ayọ̀ ni ìwọ yóò máa pọn omi
láti inú kànga ìgbàlà.
4Ní ọjọ́ náà, ìwọ yóò wí pé:
“Fi ọpẹ́ fún Olúwa, ké pe orúkọ rẹ̀,
Jẹ́ kí ó di mí mọ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,
ohun tí ó ti ṣe
kí o sì kéde pé a ti gbé
orúkọ rẹ̀ ga.
5Kọ orin sí Olúwa, nítorí ó ti ṣe ohun tí ó lógo,
jẹ́ kí èyí di mí mọ̀ fún gbogbo ayé.
6Kígbe sókè kí o sì kọrin fún ayọ̀, ẹ̀yin ènìyàn Sioni,
nítorí títóbi ni ẹni mímọ́ kan ṣoṣo
ti Israẹli láàrín yín.”