Nnwom 8 – AKCB & YCB

Akuapem Twi Contemporary Bible

Nnwom 8:1-9

Dwom 8

Dawid dwom.

1Awurade, yɛn Awurade,

wo din kɛseyɛ ada adi wiase mmaa nyinaa.

Wode wʼanuonyam

atimtim ɔsoro nohɔ,

2mmofra ne nkokoaa mpo de wɔn ano

kamfo wo, wʼatamfo nti;

na wode bɔ atamfo ne aweretɔfo ano.

3Sɛ mehwɛ wo ɔsorosoro,

wo nsateaa ano adwuma;

ɔsram ne nsoromma a

wode obiara asi nʼafa a,

4onipa ne hena a wokae no,

na onipa ba nso ne hena a wʼani ku ne ho?

5Wobɔɔ no ma ɔyɛɛ akumaa kakra sen abɔfo

na wode wʼanuonyam ne nidi abɔ no abotiri.

6Woyɛɛ no ɔsodifo maa wo nsa ano nnwuma

wode nneɛma nyinaa ahyɛ nʼanan ase:

7nguankuw ne anantwikuw nyinaa

ne wuram mmoa nso,

8wim nnomaa

ne po mu mpataa,

nea ɛnenam po mu akwan so nyinaa.

9Awurade, yɛn Awurade,

wo din yɛ kɛse wɔ asase nyinaa so!

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 8:1-9

Saamu 8

Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti gittiti. Saamu ti Dafidi.

1Olúwa, Olúwa wa,

orúkọ rẹ̀ ti ní ìyìn tó ní gbogbo ayé!

Ìwọ ti gbé ògo rẹ ga

ju àwọn ọ̀run lọ.

28.2: Mt 21.16.Láti ẹnu ọmọ ọwọ́ àti ọmọ ọmú

ni o ti yan ìyìn nítorí àwọn ọ̀tá rẹ,

láti pa àwọn ọ̀tá àti àwọn olùgbẹ̀san lẹ́nu mọ́.

3Nígbà tí mo ro ọ̀run rẹ,

iṣẹ́ ìka rẹ,

òṣùpá àti ìràwọ̀,

tí ìwọ tí gbé kalẹ̀,

4kí ni ènìyàn tí ìwọ ń rò nípa rẹ̀,

àní ọmọ ènìyàn tí ìwọ ń ṣe ìtọ́jú rẹ̀?

5Ìwọ ṣe é ní onírẹ̀lẹ̀ díẹ̀ ju Ọlọ́run lọ,

ìwọ sì dé e ní adé ògo àti ọlá.

6Ìwọ mú un jẹ ọba lórí gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ rẹ;

ìwọ sì fi ohun gbogbo sí abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀:

7àwọn agbo àgùntàn àti àwọn màlúù,

àti ẹranko igbó,

8ẹyẹ ojú ọrun,

àti ẹja inú Òkun,

àti ohun tí ń wẹ nínú ipa Òkun.

9Olúwa, Olúwa wa,

Orúkọ rẹ ti ní ìyìn tó ní gbogbo ayé!