Nnwom 47 – AKCB & YCB

Akuapem Twi Contemporary Bible

Nnwom 47:1-9

Dwom 47

Koramma dwom.

1Amanaman nyinaa, mommɔ mo nsam;

momfa anigye nteɛ mu mfrɛ Onyankopɔn.

2Awurade Ɔsorosoroni no ho yɛ nwonwa,

Ɔyɛ Ɔhene kɛse wɔ asase nyinaa so!

3Ɔde amanaman hyɛɛ yɛn ase,

na ɔde nnipa hyɛɛ yɛn anan ase.

4Oyii yɛn agyapade maa yɛn,

nea ɛyɛ Yakob a ɔdɔ no no ahohoahoade.

5Onyankopɔn aforo kɔ soro wɔ anigye nteɛteɛmu mu,

Awurade wɔ torobɛnto nnyigyei mu.

6To ayeyi nnwom ma Onyankopɔn, to ayeyi nnwom;

to ayeyi nnwom ma yɛn Hene, to ayeyi nnwom.

7Efisɛ Onyankopɔn yɛ asase nyinaa so Hene.

Monto ahurusi nnwom mma no.

8Onyankopɔn di hene wɔ amanaman no so;

Onyankopɔn te nʼahengua kronkron so.

9Amanaman no mu akunini boaboa wɔn ho ano

sɛ Abraham Nyankopɔn nkurɔfo,

efisɛ asase so ahemfo yɛ Onyankopɔn de;

na wɔma no so kɛse.

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 47:1-9

Saamu 47

Fún adarí orin. Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu.

1Ẹ pàtẹ́wọ́, gbogbo ẹ̀yin ènìyàn

ẹ hó sí Ọlọ́run pẹ̀lú orin ayọ̀ tó rinlẹ̀.

2Báwo ni Olúwa Ọ̀gá-ògo ti ní ẹ̀rù tó

ọba ńlá lórí gbogbo ayé.

3Ṣe ìkápá àwọn orílẹ̀-èdè lábẹ́ wa

àwọn ènìyàn lábẹ́ ẹsẹ̀ wa

4Ó mú ilẹ̀ ìní wa fún wa

ọlá Jakọbu, ẹni tí ó fẹ́ wa.

5Ọlọ́run tó gòkè lọ tí òun tayọ̀,

Olúwa ti òun ti ariwo ìpè.

6Ẹ kọrin ìyìn sí Ọlọ́run, ẹ kọrin ìyìn.

Ẹ kọrin ìyìn sí ọba wa, ẹ kọrin ìyìn!

7Nítorí Ọlọ́run ni ọba gbogbo ayé,

ẹ kọrin ìyìn pẹ̀lú Saamu!

8Ọlọ́run jẹ ọba lórí gbogbo kèfèrí;

Ọlọ́run jókòó lórí ìtẹ́ ìwà mímọ́ rẹ̀.

9Àwọn aládé ayé kó ara wọn jọ

gẹ́gẹ́ bí ènìyàn Ọlọ́run Abrahamu

nítorí asà ayé ti Ọlọ́run ni,

òun ni ó ga jùlọ.