Nnwom 129 – AKCB & YCB

Akuapem Twi Contemporary Bible

Nnwom 129:1-8

Dwom 129

Ɔsoroforo dwom.

1“Wɔahyɛ me so pii afi me mmofraase,

ma Israel nka ɛ.

2“Wɔahyɛ me so pii afi me mmofraase,

nanso wontumi nnii me so nkonim ɛ.

3Fɛntɛmfo afɛntɛm mʼakyi

ayɛ wɔn nkɔmoa atenten.

4Nanso Awurade yɛ ɔtreneeni;

watwitwa amumɔyɛfo hama afi me ho ama made me ho.”

5Ma wɔn a wɔtan Sion nyinaa

mfa animguase nsan wɔn akyi.

6Ma wɔnnyɛ sɛ sare a ɛwɔ ɔdan atifi,

a ennyin na ɛhyew;

7na nnɔbaetwafo ntumi nnya biribi mfi mu nhyɛ ne nsa ma,

na nea ɔboaboa ano nso nnya hwee nhyɛ nʼabasa ma.

8Mma wɔn a wotwa mu wɔ hɔ no nka se,

Awurade nhyira mmra mo so;

yehyira mo wɔ Awurade din mu.”

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 129:1-8

Saamu 129

Orin fún ìgòkè.

1“Ìgbà púpọ̀ ni wọ́n ti pọ́n mi lójú

láti ìgbà èwe mi wá”

ni kí Israẹli kí ó wí nísinsin yìí;

2“Ìgbà púpọ̀ ni wọ́n ti pọ́n mi lójú

láti ìgbà èwe mi wá;

síbẹ̀ wọn kò tí ì borí mi.

3Àwọn awalẹ̀ walẹ̀ sí ẹ̀yìn mi:

wọ́n sì la aporo wọn gígùn.

4Olódodo ni Olúwa:

ó ti ké okùn àwọn ènìyàn búburú kúrò.”

5Kí gbogbo àwọn tí ó kórìíra Sioni kí ó dààmú,

kí wọn kí ó sì yí ẹ̀yìn padà.

6Kí wọn kí ó dàbí koríko orí ilẹ̀

tí ó gbẹ dànù kí ó tó dàgbàsókè:

7Èyí tí olóko pípa kó kún ọwọ́ rẹ̀:

bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ń di ìtí, kó kún apá rẹ̀.

8Bẹ́ẹ̀ ni àwọn tí ń kọjá lọ kò wí pé,

ìbùkún Olúwa kí ó pẹ̀lú yín:

àwa ń súre fún yin ní orúkọ Olúwa.