Nnwom 1 – AKCB & YCB

Akuapem Twi Contemporary Bible

Nnwom 1:1-6

ƆFA A EDI KAN

Nnwom 1–41

Dwom 1

1Nhyira ne onipa a

ontie amumɔyɛfo afotu

na onni nnebɔneyɛfo nhwɛso akyi

na ɔntena fɛwdifo tenabea.

2Na mmom, Awurade mmara sɔ nʼani,

na osusuw ho awia ne anadwo.

3Ɔte sɛ dua a wɔatɛw wɔ asuten ho,

na ɛsow nʼaba ne bere mu a

nʼahaban no nguan da.

Nea ɔyɛ biara yɛ yiye.

4Nanso nnebɔneyɛfo nte saa;

wɔte sɛ ntɛtɛ a

mframa bɔ gu.

5Enti amumɔyɛfo rentumi nnyina atemmu no ano,

na nnebɔneyɛfo nso rentena atreneefo asafo mu.

6Efisɛ Awurade kyerɛ ɔtreneeni kwan

nanso amumɔyɛfo kwan de, ɛbɛyera.

Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn

Saamu 1:1-6

ÌWÉ KÌN-ÍN-NÍ

Saamu 1–41

Saamu 1

11.1-3: Jr 17.7-8.Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà,

tí kò rìn ní ìmọ̀ àwọn ènìyàn búburú,

ti kò dúró ní ọ̀nà àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀,

tàbí tí kò sì jókòó ní ibùjókòó àwọn ẹlẹ́gàn.

2Ṣùgbọ́n ayọ̀ inú rẹ̀ wà nínú òfin Olúwa

àti nínú òfin rẹ̀ ni ó ń ṣe àṣàrò ní ọ̀sán àti òru.

3Ó dàbí igi tí a gbìn sí etí odò tí ń sàn,

tí ń so èso rẹ̀ jáde ní àkókò rẹ̀

tí ewé rẹ̀ kì yóò rẹ̀.

Ohunkóhun tí ó dáwọ́lé, ni yóò máa yọrí sí rere.

4Kò le rí bẹ́ẹ̀ fún àwọn ènìyàn búburú!

Wọn yóò dàbí ìyàngbò ọkà

tí afẹ́fẹ́ ń fẹ́ dànù.

5Nítorí náà àwọn ènìyàn búburú kì yóò le è dìde dúró ní ìdájọ́,

bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ kì yóò le è dúró ní àwùjọ àwọn olódodo.

6Nítorí Olúwa ń ṣọ́ ọ̀nà àwọn olódodo,

ṣùgbọ́n ọ̀nà àwọn ènìyàn búburú ni yóò ṣègbé.